Yemi Adenuga: Olùdìbò Ireland kìí gba ìrẹsì, àmọ́ wàá dé ilé kọ̀ọ̀kan láti bèèrè ìbò
Agbohunsafẹfẹ ni Yemi Adenuga lorilẹede Naijiria ko to lọ tẹdo si orilẹede Ireland lọdun 2000.
Lọdun 2019 ta wa yii si lo dibo wọle gẹgẹ bii Kanselọ alawọ dudu akọkọ ti wọn yoo dibo yan lorilẹede Ireland.
Nigba to n ba BBC Yoruba sọrọ, Yemi Adenuga ni o se ni laanu pe awa alawọ dudu gangan ni ọta ara wa nitori awọn ọmọ Naijiria gan lo dide tako oun pe oun ko ni wọle ibo kanselọ naa.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Èmi àti Bọla Tinubu fẹ́ lo ‘German Mercenaries’ láti gbé MKO Abiọla kúrò lẹ́wọ̀n - Dele Momodu
- ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin
- Àlàyé rèé lórí bí wọ́n ṣe mú mi lẹ́rú ní 1837 - Ajayi Crowther
- Mo nífẹ̀ẹ́ Khafi torí kìí díbọ́n tàbí hùwà oníwà - Gedoni sọ̀rọ̀ ìdágbére
- Àwọn alálẹ̀ kò ní forí jìn mí tí ń kò bá ṣe ọdún Ṣàngó - Alaafin
O ni awọn oludibo ni Ireland kii beere fun owo, asọ, ororo, irẹsi abi tomato, ohun kan soso ti eeyan gbọdọ se ni lati polongo ibo lọ si ojule kọọkan fun awọn oludibo.
Adenuga fikun pe, bi ilu se ri lo gbe oun kuro ni Naijiria, to fi mọ ọrọ ẹbi oun, wiwa ọjọ ọla fun awọn ọmọ ati ki iya oun lee jẹ ounjẹ ọmọ lọjọ alẹ.
- Irọ́ ńlá! Ẹgbẹ́ IPOB ò tako Ààrẹ Buhari ní Japan- Iléeṣẹ́ Ààrẹ
- Òfin nìkan ló lè gbadé lórí àwa Ọba ìlú lbadan- Oba Lekan Balogun
- ‘Pussypedia’ rèé, ojú òpó tó ń mú àdínkù bá ìṣòro ìmọ̀ nípa ẹ̀yà ara obìnrin
- To bá fẹ́ jàǹfààní iná ọba tí kò ṣẹ́jú látọ̀dọ̀ ìjọba, ọ̀nà ẹ̀bùrú tó gbà rèé
- Omi ara Ọ̀pọ̀lọ́, ẹ̀jẹ̀ Ẹlẹ́dẹ̀ àti wáìnì tí wọn fi Èkúté ṣe ń mára jípépé, ẹ máa mú
- O dùn mí pé Buhari kò yàn mí sípò Mínísítà lẹ́ẹ̀kejì àmọ́ mò gbà kádàrá - Adebayo Shittu
Kanselọ alawọ dudu akọkọ ni Ireland naa wa rọ awọn ọmọ Naijiria nile ati loke okun, lati mu ayipada rere ba orukọ buruku ti wọn sọ orilẹede Naijiria lẹyin odi, ka si jẹ ki wọn mọ pe ohun rere lee ti orilẹede Naijiria jade wa, gẹgẹ bi oun ti se.