Osun Osogbo: Ọdọọdún ni Àtáója ń gbàlejò gbogbo Arugbá lásìkò ọdún Ọ̀ṣun Òṣogbo
Ọdọọdun laa ri orogbo, ọdọọdun laa ri awusa, ọdọọdun si laa ri ọmọ obi lori atẹ, amọdun ko si jinna, kẹni ma ri eebu sun jẹ.
Bẹẹ lọrọ ri pẹlu ọdun Ọṣun Ọṣogbo fun tọdun 2021, eyi to ti ko bayii titi di ọṣe to m bọ.
Ara awọn eto ti wọn fi n sami ọdun Ọṣun Ọṣogbo si ni ipejọpọ awọn arugba ni aafin Ataoja tilu Osogbo eyi ti a waye bayii.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Dáa padà! Àwa kìí ṣe ẹgbẹ́ kan náà pẹ̀lú APC tó dojú Nàìjíríà kodò -PDP sí Jega
- Ìjọba Amẹ́ríkà ti kó abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 mílíọ̀nù mẹ́rin fún Nàìjíríà
- Àjẹ́ àti Aṣẹ́wó ní ìyá Rainbow - Òjòpagogo
- "Ẹ̀yin obìnrin, ẹ lọ kọ́ iṣẹ́ káfíńtà torí ó lówó lórí ju iṣẹ́ aránṣọ lọ"
- Àwọn ọmọbíbí ìpínlẹ̀ Ọyọ nìkan ni yóò rí iṣẹ́ àgbàṣe gbà lábẹ́ ìjọba mi - Seyi Makinde
- Njẹ́ o mọ̀ pé bíi ọdún 700 sẹ́yìn ni wọ́n ti ń bọ Osun-Osogbo? Mọ̀ síi nípa ìtàn ojúbọ̀ nàá
Nigba to n salaye ayẹyẹ igbalejo naa, agba ọjẹ kan nilu Osogbo salaye pe, ọna lati fi ẹmi imoore han si gbogbo awọn obinrin to ti ru igba Ọṣun sẹyin lo mu ki Kabiyesi gba wọn lalejo.
Nibi ayẹyẹ igbalejo naa to maa n waye lọdọọdun, ni awọn arugba yoo ti maa jo yika igba Ọṣun, eyi to fihan pe isẹ igba ruru ti wọn se ko ja si asan.
A gbọ pe ifa lo maa n fa ọmọge ti yoo ru igba Ọṣun kalẹ laarin awọn ọmọbinrin ti Ataoja to wa lori oye ba bi.
- Afọnja, ẹni tó finú wénú ní Ilọrin, àmọ́ tó jẹ iwọ
- 5:30 p.m ni ojú mi déédé fọ́ níbi tí mo ti ń darí ọkọ̀ ni Ọrẹgun Ikẹja -LASTMA Yesufa
- Mo ti kó kúrò nílé Olu Jacobs rí lẹ́ẹ̀mejì- Joke Silva
- "Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"
- Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun
Ọmọge ti ifa ba si mu yii ko gbọdọ tii mọ ọkunrin, yoo si se isẹ naa titi ti yoo fi wọ ile ọkọ ni.
O ya, ẹ jẹ ka wo bi ayẹyẹ ipejọpọ gbogbo awọn Arugba se lọ nilu Oṣogbo lasiko ọdun Ọṣun Ọṣogbo fun tọdun yii.
- Ayédèrú Ọ̀ṣun ni wọ́n ń bọ lónìí, kìí ṣe ojúlówó - Bàbá Ọlọ́ṣun tún figbe ta
- Wo ọ̀nà tí orin gbígbọ́ fi ń ṣèrànwọ́ f'ọpọlọ ọmọ ìkókó
- Ìjọba Amẹ́ríkà ti kó abẹ́rẹ́ àjẹsára Covid-19 mílíọ̀nù mẹ́rin fún Nàìjíríà
- Ẹ fún wa ní oṣù márùn ún láti fí lé àwọn ajínigbé Fulani kúrò nínú igbó- Olórí Fulani
- Kí ló mú kí géńdé múra bí obìnrin láti bá ọ̀rẹ́bìrin rẹ̀ kọ ìdánwò?