AFCON 2019: Ki akọnimọọgba Naijira bá wọn sọ̀rọ̀ kóríyá
Ọpọ tun yanana pé ki akọnimọọgba Naijiria ranti awọn aṣiṣe to ṣẹlẹ ninu idije to kọja.
Nigba ti BBC Yoruba fọrọ wa awọn ololufẹ Super Eagles lẹnu wo lori idije toni, ọpọ wọn lo fadura ranṣẹ si awọn agbabọọlu wa ni Egypt
Nigba ti awọn miran n fun wọn ni imọran ki wọn le bori idije wọn pẹlu orilẹ-ede Tunisia ti wọn jo n dije du ipo kẹta.
- A ti wọ́gilé ìwọ́de lórí COZA tí a fẹ́ ṣe tẹ́lẹ́ nítorí...
- Ẹ padà sílé èyin ọmọ wa tó n ṣiṣẹ́ darandaran - NEF ti Fulani
- Buhari ti buwọ́lu ẹ̀kúnwó sísan owó oṣù tuntun fáwọn òṣìṣẹ́ àpapọ̀
- Ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ TUC fárígá sí ìjọba Naijiria lórí owó oṣù tuntun
- Super Eagles gba iṣẹ́ lọ́wọ́ Seedorf olùkọ́ni Indomitable Lions Cameroun