Aago mẹ́ta òrú ní Joseph ẹni ọdún 65 dáná sún àwọn ọmọ ti Esther ẹni ọdún 35 kò wá fẹ́ ẹ
Ọsẹ to m bọ ni mo pinnu lati ko awọn ọmọ mi sọdọ ki ọkọ tuntun ti iyawo mi fẹ to dana sun wọn- Akinfolarin Liadi
BBC wa arabinrin to bi ọmọ marun un ti wọn jona mọle ni Ondo kan lati mọ ohun to ṣẹlẹ gangan.Ọlọ́pàá mú ọkùnrin tó d-áná sun ọmọ ìyàwó rẹ̀ márùn-ún ní Ondo
Esther Ojo to jẹ ẹni ọdun marundinlogoji ṣalaye fun BBC Yoruba pe lẹyin ti oun kọ Liadi silẹ ni oun lọ fẹ Joseph ẹni ọdun marunlelọgọta.
O bimọ meji fun Joseph Ojo, o si ko ọmọ marun un to bi tẹle fun Liadi wa sile Joseph.
- Alága EFCC tó ṣe àìgbọràn sí àṣẹ ilé ẹ̀jọ́ ló yẹ́ kó lọ sí ẹ̀wọ̀n kìí ṣe Bawa - EFCC
- Adájọ́ pàṣẹ pé kí wọ́n lu génde méjì, kí wọ́n tún gbálẹ̀ ilé ẹjọ́ nítorí Tiktok
- Wó ìdí tí àwọn akẹgbẹ́ Uchechi Nwachukwe ṣé ṣekúpa á ní Owerri
- À-wọn Òbí àwọn ọmọ tí oògùn ikọ́ pa kọ̀ láti gba $20-000 owó gbà-má-bínú tíjọba fún wọn
- Mọ̀ sí i nípa ètò ìdìbò ilé ìgbìmò asòfin Amẹrika
- Báwo ní akẹ́kọ̀ọ́ fásitì 'Michael Okpara' méjì ṣé kú sínú iyàrá lójú oorun-

BBC tun wa Arakunrin Akinfolarin Liadi to jẹ baba awọn ọmọ to jona naa kan.
O salaye ipinnu rẹ lati mu awọn ọmọ naa sọdọ ṣaaju iṣẹlẹ yii ati ohun ti oun mọ nipa iṣẹlẹ naa pẹlu ibanujẹ.
Awọn ọlọpaa ti mu Joseph Ojo to dana sun awọn ọmọ naa bayii.
Meji ninu wọn si ti ku ni asiko ti a n ṣe ifọrọwanilẹnuwo yii.
- A kò sọ pé kí Nàíjíríà má pìn-ín, ọ̀rọ̀ wa ti di òrìṣà bó ò le gbè mí, ṣe mi bó o ṣe bá mi – Sowore
- À-gùtàn di èrò àtímọ́lé ọlọ́pàá lẹ́yìn tó jẹ ẹja díndín lórí igbá onígbá
- Àwọn ilé, ilẹ̀ Ike Ekweremadu tó lé ní 40 tí EFCC gbà tí wọ́n fẹ́ tà rèé..-
- Owó Náírà tí kò lè ra búrẹ́dì ni àwọn ọ̀ga wá fẹ́ ṣé àtúnṣe si - Adeboye
- Pásítọ̀ Davido àti Chioma sọ̀rọ̀ síta lórí ipò tí tọkọ-taya wà