Lateef Adedimeji ti gbé Adebimpe Oyebade ní ìyawó

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Gbajumọ oṣere tiata Yoruba, Lateef Adedimeji ti gbe akégbẹ rẹ nidi iṣẹ tiata, Adebimpoe Oyebade niyawo.

Igbayawo naa waye niluu Ikole Ekiti, ni ipinlẹ Ekiti, nibi ti ọpọ ero peju si.

Ṣaaju ni Lateef ti kọkọ sọ fun BBC Yoruba ninu ifọrọwanilẹnuwo kan pe lootọ ni awọn mejeji yoo ṣe igbeyawo laipẹ.

Ifọrọwanilẹwo naa ni igba akọkọ ti Lateef yoo sọ fun awọn akọrọyin pe lootọ ni awọn mejeji yoo di tọkọ-taya, bo tilẹ jẹ pe awọn ololufẹ wọn ti kọkọ sọrọ nipa igbeyawo naa lori ayelujara ṣaaju.

Lẹyinorẹyin, Lateef gbe Adebimpe niyawo lọjọ kejidinlogun, oṣu kejila, ọdun 2021 yii.

Awọran bi eto igbeyawo naa ṣe lọ ree.

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

ADEBIMPE OYEBADE

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

ADEBIMPE OYEBADE

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA

Latef Adedimeji

Oríṣun àwòrán, EMIRALTY AFRICA