Samuel Oluwafemi sọ bí Covid 19 ṣe bí ìdíje oníjó àti eré fún àwọn Odi àti Adití sí rere
Mo fẹ́ràn láti máa kó Odi àti aditi ni, kódà, ọ̀kan nínú wọn ni aya ti mo fẹ́ sílẹ̀- Samuel Oluwafemi
Ogbeni Samuel James Olufemi gbalejo BBC Yoruba nibi to ti n kọ awọn to ni ipenija ara ni ijo jijo ati ere itage ni ṣiṣe.
O salaye bi irinajo yii ṣe bẹre lọdun 2007 nigba to lọ kọ nipa ọna ibanisọrọ nipa lilo ọwọ lẹyin to ka nipa ere itage nile ẹkọ giga.
- Ẹ̀yin ọmọ Yoruba ẹ darapọ̀ mọ́ wa látí tako ìjọba Naijiria lórí àtìmọ́lé Nnamdi Kanu - IPOB
- Àṣírí ọ̀rọ̀ àti dúkìá ìkọ̀kọ̀ ẹbí aarẹ Uhuru Kenyatta tú
- Àwọn dókítà tí fagilé ìyanṣẹ́lódì ọlọ́jọ́ gbọọrọ, sùgbọ́n...
- Ṣé Facebook, Instagram, WhatsApp ti yín náà ti dẹnukọlẹ̀? Ìdí tó fi ṣẹ́lẹ̀ rèé...
- Ẹ yé kóra jọ pọ̀ láti d'ẹ́rù ba ni pé ọwọ́ Yorùbá ni Ààrẹ 2023 gbọ́dọ̀ bọ́ sí- Shekarau
- Wo Samuel James tó ń kọ́ Odi àti Adití ni ijó àti eré ìtàgé, fún ojú lóúnjẹ ayọ̀

- Olubadan ti ilẹ̀ Ibadan rọ Báàlẹ̀ Lagelu Abọke kúrò lóyè lórí ẹ̀sùn aṣemáṣe
- Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ àwọn ajínigbé níbi tí wọ́n ti ń gba owó ìtúsílẹ̀ ẹni tí wọ́n jígbé
- Láti ọdún mẹ́rin sẹ́yìn ìjọba Mozambiqe ni àwọn kò mọ agbésùmọ̀mí níbẹ̀
- Ṣé o ti gbọ́ nípa ìlú tí ara sísan ti jẹ́ dandan fún àwọn ọmọbìnrin?
- Àyájọ́ Olùkọ́ lágbayé-Nígbà wò ní owó oṣù tuntun fáwọn olùkọ́ yóò di gbígbà?
- Àwọn agbègbè ní ìpínlẹ̀ Eko rè é tí kò ní gbádùn iná ọ̀ba fún ọ̀sẹ̀ mẹ́jọ...
Samuel James Oluwafemi to jẹ ọmọ bibi Ado odo Ota ni ipinlẹ Ogun ṣalaye nipa awọn ipenija ti awọn akẹkọọ yii n dojukọ ni awujọ.
O tun mẹnuba bi iṣẹlẹ Coronavirus ati konile o gbele 2020 se fun wa ni aaye lati ṣe awọn idije kọọkan fun awọn akẹkọọ Odi ati Aditi naa.
