Sunday Igboho's latest on Oduduwa Republic: Ìràn Yorùbá ò ní ìṣọ̀kan rárá ló ń fa gbogbo èyí
Awọn agbaagba ilẹ Yoruba ti korajọ nilu Ibadan, ipinlẹ Oyo láti jọ jiroro lorii aṣeyọri orilẹede Yoruba ti wọn n ja fun.
Alagba Taiwo Oyerinde to jẹ ọkan lara wọn ni ọpọlọpọ ọmọ Yoruba lo ti kọ iwe si ajọ isọkan agbaye ti wọn n pe ara wọn ni oniruuru oye tori onikaluku fẹ maa gba oriyin, "wọn o ṣe e tori ilu, bikoṣe tori orukọ wọn".
Ipade naa waye laarin apapọ gbogbo ẹgbẹ Yoruba lagbaye ni ilu Ibadan tii ṣe olu ilu ipinlẹ Oyo.
"Awọn kan wa to jẹ pe wọn ti jẹ dodo wọn le sọ ododo mọ tori nkan ti wọn fẹ da".
- 'Èmi àti ìyàwó mi ti ń gbé pọ̀ nínú ìgbéyàwó wa fún 60 years', ẹ wá kọ́ ẹ̀kọ́ lẹ́nu àgbà
- Kò sí olóṣèlú tí wọ́n fi tọ́ lẹ́nu wò pé kó di ààrẹ Naijiria ní 2023 tí kò ni tọ ọ́ lá - Fayemi
- Ọwọ́ agbófinró tẹ obìnrin tó gbé 'cocaine' sínú ojú ara rẹ̀ l'Abuja
- Gómìnà máa ń tẹ̀ lẹ́ẹ̀kọ̀ọ̀kan láti wa ojú iré ìjọba apapọ̀, àmọ́ ọmọ wa náà ṣì ni Akeredolu - Banji Akintoye
- Àìgbọ́ra ẹni yé ẹ̀yà Yoruba ló ń ṣe ìdíwọ́ fún òmìnira wa - Àkójọpọ̀ ẹgbẹ́ Yoruba l'àgbáyé
- Ẹ̀yà Yorùbá ti fara ṣiṣẹ́ púpọ̀ fún Naijiria, nítorí nàá à kò le déèdé sọ pé a fẹ́ kúrò - Àgbààgbà Yorùbá
- Ẹ kó àwọn ọmọ yín lọ sílé ẹ̀kọ́ àwọn Musulumi tí ẹ bá fẹ́ kí wọ́n máa lo Hijab - Oyedepo
- Àlùwàlá ológbòò Tinubu pẹ̀lú ₦50m tó f'áwọn ará Katsina, ọgbọ́n àti kẹ́ran jẹ nínú ìbò 2023 ni
- Ẹ̀rù bà mí pé òpin iṣẹ́ yìí ti dé lásìkò Covid-19 àmọ́ àwọn àga tó pawó wọlé fún mi rèé - Obìnrin oní fọ́nííṣọ̀
O ni gbogbo eyi lo maa n mu ọrọ alunfanṣa jade lẹnu awọn Yoruba sirawọn.
Ẹlomiran ni aisi ifọwọsowọpọ lo n fa aisi irẹpọ laarin iran Yoruba.
Wọn tun ṣepade yii lori pe wọn ni lati pawọpọ ki awọn ipenija to n koju iran naa le di afisẹyin bi eegun ṣe n fi aṣọ.

