Africa Eye: Ọmọ ìgboro méje tó ń jò tà di aláṣeyọrí
Yoruba ni ẹni ti ko ba le se bi alaaru ni Oyingbo, ko le se bi Adegboro ni ọja ọba, ẹni ti yoo si ga, ẹsẹ rẹ yoo tiirin.
Owe yii lo ba awọn gende meje kan mu, ti wọn dagba soju popo lai ri isẹ oojọ kankan se, wọn ko nile lori bẹẹ naa si ni wọn ko ri ẹni fẹyin ti.
Awọn gende yii ko ri ọwọ mu lọ sẹnu, ti wọn si n gbe igbe aye wọn bi alaini ẹnikan, koda oju wọn n ri mabo loju popo ti wọn dagba si.
Àwọn iwadii ọtẹlẹmuyẹ Africa Eye tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìwádìí fídíò ayélujára tú àṣìrì ìpànìyàn Boko Haram
- BBC tún gbé e dé! Wọ́n tú àṣírí ìfiyàjẹni àwọn Ológun àti SARS káàkiri Nàìjíríà
- Ẹ̀rí tuntun BBC Africa Eye yìí tú àṣírí ohun tó ṣẹlẹ̀ gangan nínú ìbúgbàmù Abule Ado
- "Shrine" ni wọ́n ń pé ọ́fíísì wa táa ti ń sanwó òṣìṣẹ́fẹ̀yìntì", BBC Africa Eye tú àṣírí wọn
- Àkàrà tú sépo! Ikọ̀ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ BBC tú àṣírí bí SARS ṣe ń fìyà jẹ aráàlú
- Mi ò mọ nkankan nípa ọmọ Nàìjíríà tó n fi àwọn obìnrin ṣe aṣẹ́wó ní India - Abike Dabiri
- Bí ìròyìn BBC nípa oògùn ikọ́ Codeine ṣe ń tún ayé tó ti bàjẹ́ ṣe
- Akànṣẹ́ àti alákòso Aṣẹ́wó
- 'Nínúu ká ṣe oríire níbí tàbí káa kú'! Àwọn tó ń fẹsẹ̀ rìn sálọ orílẹ̀èdè míì ṣe fídíò ráńṣẹ́ sílé
- 'Kìí ṣe àròsọ, mo ní fọ́nrán fídíò àwọn ẹlẹyẹ ìlú mi'
Idi ree ti ẹka iwadi ọtẹlẹmuyẹ BBC nilẹ Afirika se n tẹle wọn lẹyin lati finmu finlẹ mọ ibi ti ọrọ aye awọn gende meje naa yoo pada yọri si.
Amọ lẹyin ọdun meji, ori awọn ọmọ naa pada wa sọre, oju popo naa si ni wọn ti rinna pade oloore wọn.
Ijo jijo loju popo ti wọn yan laaye gbe wọn de ibi giga, ti wọn si kuro ni ojo popo.



