Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa

Àkọlé fídíò, Adejare Adeboye: Olúwa yóò dá gbogbo ohun ta sọnù ní 2020 padà ní ilọ́po méje fún wa

Yoruba ni ohun to ba dara n fẹ adura, bakan naa ni ohun to ba ku diẹ kaato.

Ọpọ Ijakulẹ lọmọ Naijiria ba pade lọdun 2020 to kogba wọle, idi ree ta fi nilo ọpọ adura ninu ọdun tuntun 2021 ta bẹrẹ yii.

Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:

Eyi lo mu ki BBC Yoruba tọ ọkan lara awọn ilumọọka ojisẹ Ọlọrun ni Naijiria, Pasitọ Enoch Adejare Adeboye lọ, pe ko fi ojo adura bẹrẹ ọdun tuntun fun gbogbo wa.

Baba gbadura, ilẹ kun, ẹ wo fidio adura yii, kẹ si maa se amin witiwiti.