NSCDC ṣèèṣì yìnbọ̀n pa ọlọ́pàá ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́ DSS l'Osun

Oríṣun àwòrán, NSCDC
Ọkan lara awọn oṣiṣẹ ajọ abo ara ẹni laabo ilu, NSCDC, Sunday Dade ṣeeṣi yinbọn pa ọlọpaa ọtẹlẹmuyẹ DSS kan Seyi Adebowale nipinlẹ Osun.
Iṣẹlẹ naa ni a gbọ pe o ṣẹlẹ ni aafin ọba to wa ni Kuta, ijọba ibilẹ Ayedire nibi ti Gomina Adegboyega Oyetola ti lọ ṣi afara kan ti ileeṣẹ ọmogun ilẹ kọ.
Ohun ti a gbọ ni pe Dade n yinbọn soke pẹlu idunnu nigba ti wọn n ṣi afara naa lẹyin naa ni ọta ibọn ti ṣeeṣi ba Adebowale.
- MC Murphy ko sọ òótọ́ ọ̀rọ̀ to wà níbẹ̀, tó ba wùú kó sọ òótọ- Adebayọ
- Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams
- Ikú tó ń pa ojúgbà ẹni..., kí ni ìparí òwe náà?
- Ìtàn tó rọ̀ mọ́ òwe ‘aṣọ kò bá Ọ́mọ́yẹ mọ́...’ rèé
- Mo ká ọkùnrin mọ́ ìyàwó mi lórí, ẹ má gbọ́ ẹjọ́ ẹnìkan dá o! - Femi Fani-Kayode
- Làásìgbò òṣèlú wáyé nílùú Ondo, ọ̀pọ̀ èèyàn fara pa
Agbẹnusọ fun ajọ NSCDC, Adigun Daniel to fidi iṣẹlẹ ọhun mulẹ ṣalaye pe eṣi lo ṣe fun Dade, ko mọọ mọ yinbọn fun un.
O ṣalaye siwaju sii pe Dade ti n jẹjọ bayii lori iṣẹlẹ naa.
Ọga agba ileeṣẹ ọmogun ilẹ ni Naijiria, Tukur Buratai naa wa ni ibi ayẹyẹ ṣiṣi afara ọhun.








