Press freedom: Ohun tó ń fa ojúkòkòrò fún àwọn akọ̀ròyìn nìyìí

Àkọlé fídíò, 'Mo rántí, láyé ìjọba ológun... ohun tójú oníròyìn ń rí'

Agba ọjẹ akọroyin ni Emmanuel Malagu jẹ, bẹẹ naa si ni, o ti foju wina ọpọlọpọ iriri ti ko ṣee ro tan.

Ninu ojo, ninu ẹrun, iṣẹ́ iṣẹ́ ni, bẹẹ ni tawọn oniroyin n ri paapaa ju lọ ni akoko yii to jẹ wi pe laarin iṣẹju aaya ni awọn eniyan fi n ka iroyin bayii.

Lati ọdun 1980 ti Malagu Emmanuel ti bẹrẹ iṣẹ oniroyin, o ni ọ̀rọ̀ pọ ninu iwe kọbọ lo ṣe tẹnu bọ ọ̀rọ̀ pẹlu BBC Yoruba.