Taiwo Awoniyi, Nottingham Forest, Sport: Ìlú Oyìnbó kò rọrùn ṣùgbọ́n mo dúpẹ́ ibi tí orí, Olúwa, ẹbí àti ará gbé mi dé báyìí
Mo kọ̀ láti gbàgbé ilé àti orísun mi ni mo ṣe padà wá n pèsè ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ọ̀dọ́ ní Ilorin,
Taiwo Awoniyi Michael lo jẹ ojulowo ọmọ Naijiria to n gba bọọlu fun Nottingham Forest ni England to dide lati Ilorin ni ipinlẹ Kwara ni Naijiria lati maa gba bọọlu lati ọmọ ọdun meje.
O ni oun mọọmọ n pada wa si Ilorin lati wa fi imoore han fun orisin oun ni.

Taiwo Awoniyi sọ nipa awọn idojukọ rẹ ko to moke ninu bọọlu gbigba.
O sọ bi o ṣe maa n fi ẹsẹ rin lati adugbo Agboọba fun wakati kan o le ko to de ori papa to ti n kọ bọọlu gbigba.
O gba awọn ọdọ nimọran lati ni suuru ki wọn si ṣọra ki enikeni ma fi ilu oyinbo tan wọn jẹ.
- Wo ọkùnrin tó ń wọ àṣọ ìdámọ̀ Nàíjíríà lójoojúmọ́ láti wá ire orílẹ̀èdè yìí.
- N kò ríran àmọ́ ó rọrùn fún mi láti ṣiṣẹ́ akọ́nimọ̀ọ́gbá èré bọ́ọ̀lù - Babatunde Kareem
- ''Ẹ̀yín òbí tí ẹ bí àfín, wo ohun tẹ́ ẹ ṣe kí ọmọ̀ yín máṣe ní àrùn jẹjẹrẹ bíi tèmi
- Àsìkò wo ló yẹ kí obìnrin bẹ̀rẹ̀ ìbálòpọ̀ padà lẹ́yìn ìbìmọ láìséwu?
- 'Ifá ló mú èmi o! Ẹnu iṣẹ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n Fásitì ni mo wà tí wọ́n ní kí n wa jẹ Olota ti ìlú Ota'
- 'Mo n bẹ ọlọ ata, òpó iná, tọ̀ sínú ẹ̀yìn iná lálẹ́, kí ń má baà tọ̀ sílé lóru'
- Mọ̀ síi nípa ewu tó rọ̀ mọ́ níní ìbálòpọ̀ lásìkò ìlóyún lórí ètò Sé lóòtọ́ ní BBC
