Olufemi Ajadi Oguntoyinbo: Oṣù méjì tí mo bá dé ìjọba ni àwọn ará ìpínlẹ̀ Ogun a ti rí àyípadà rere tó pọ̀
Mo fẹ ṣe ayipada si igbe aye awọn eeyan mi ni mo ṣe jade dije dupo gomina Ogun- Ajadi Olufemi
Asoju Olufemi Ajadi Oguntoyinbo ṣalaye fun BBC pe nitootọ ni oun ko ni iriri ninu iṣelu to pọ tẹlẹ ṣugbọn oun ṣetan lati mu inu awọn eeyan ipinle Ogun dun.
Oun lo jade dupo gomina labẹ ẹgbẹ oṣelu Naijiria tuntun ti wọn pe ni New Naigeria People's Party.
O sọ bi ohun to ṣẹlẹ ni 1993 lẹyin wahala June 12 Moshood Kashimaawo Olawale Abiola da rogbodiyan sile nigba naa ni ninu ipinnu oun.
- Ìjọba Osun gbé orúkọ àwọn tí ọkọ̀ ìjọba tí iyé rẹ̀ tó #2.9bn wà lọ́wọ́ wọn jade
- Àhámọ́ ọlọ́pàá ni Adeyẹmi, ọmọ gbajúmọ̀ Ọba yóó ti ṣọdún Kérésìmesì
- Ibi tí o bá dágbére fún ẹbí àti ará ní kí wọ́n ti ba ọ lásìkò ọdún Kérésì yìí- Akọ́ṣẹ́mọ́ṣẹ́ Bolarinwa
- Ká má tan ara wa jẹ, àwọn tó ń pè fún Yoruba Nation kò lè ṣàṣeyọrí – Akeredolu
- Wo àwọn gbajúmọ̀ òṣèré Yorùbá tó jẹ́ ọmọ ẹ̀yà míì àti orílẹ̀èdè míì
- Mọ̀ síi nípa Bola Ige tó jẹ́ mínístà ètò ìdájọ́ ṣùgbọ́n tí wọ́n ṣì ń wá ìdájọ́ òdòdo lórí ikú rẹ̀
- Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa adẹ́rínpòṣónú, Peteru tó jáde láyé
Nakan naa ni Ajadi sọrọ nipa ijakule ti awọn egbẹ oṣelu ti ko ba awọn ara ilu atyi ohun to pinnu lati ṣe fun awọn eniyan ipinlẹ Ogun laarin oṣu meji ti oun ba gba ijọba.