Gomina Adegboyega Oyetola sọ ibi ti iṣẹ́ dé dúró nípinlẹ̀ Osun lórí ètò BBC Yoruba
Emi kii parọ rara, ohun ti mo ba fẹ́ ṣe ni mo maa n sọ- Gomina Oyetola
BBC Yoruba seto ipade itagbangba nilu Osogbo ni ipinle Osun ki awon oludibo le raaye mọ sii nipa awọn oludije sipo gomina nibẹ.
Lara awọn to wa sibi eto naa ni Gomina Adegboyega Oyetola to n tuko ipinle Osun bayii.
Lati ọdun 2018 ni gominaa naa ti gori aleefa lẹyin ti Ogbeni Rauf Aregbesola fi ipo naa silẹ,.
Adegboyega Oyetola salaye nipa awon ileri rẹ to ti muṣẹ lati igba to ti gori aleefaGbọ́ ohun tí àwọn olùdíje sípò gómìnà ìpínlẹ̀ sọ níbi ìtàkurọ̀sọ BBC Yoruba.
- Àwọn nkán tí ẹni tó bá fẹ́ pa ẹran ileya kó gbọ́dọ̀ ṣé ní ìpalẹ̀mọ́ dé ọdún Eid-il-Adha
- Ìjọba gbọ́dọ̀ fi páńpẹ́ ọba mú CJN tẹlẹ̀, ìfipòsílẹ̀ kò tó – Huriwa
- Ènìyàn mẹ́sàn án ti kú ní ìfẹ̀họ́núhàn tako ìjọba ológun
- Ilé ẹjọ́ dá ẹ̀wọ̀n ọdún 235 fún Olatunji Ishola lórí ẹ̀sùn jìbìtì owó lórí ayélujára ní Uyo
- Portable yọjú sí àgọ́ ọlọ́pàá, ẹ wo ibí tí ọ̀rọ̀ kángun sí