Femi Babalola: Mo tá iṣẹ́ ọnà kan ni mílíọ̀nù kan rí, kódà mo n fi egungun ẹja, irin, amọ̀ àti igi dárà tó wù mí
Kò sí iṣẹ́ tó lè pa owó wọlé tó iṣẹ́ ọ̀nà tí mo ń ṣe yìí- Femi Babalola
Femi Babalola to n siṣẹ agbegilere lo gba BBC Yoruba lalejo.
O sọ bi o ṣe bẹrẹ irinajo rẹ lati kekere to n ba awọn akẹgbẹ rẹ ṣe iṣẹ amurele to dẹ n gba owo lọwọ wọn.
- Wo orílẹ́èdè tó fẹ́ fi òfin de sìgá mímú fún ìran ọmọ wọn tó ń bọ̀
- Mọ̀ sií i nípa Oba Yesufu Asanike , Olubadan tí kìí fi ọ̀rọ̀ sí abẹ́ ahọ́n sọ kódà níwájú sọ́jà
- Àkójọpọ̀ àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ tó dára àti èyí tó burú tó wáyé ní 2020
- Wo bí wọ́n ṣe sin Ọba Satani pẹ̀lú ọkọ̀ àti orin tó fẹ́ràn jù
- Ìdí tí wọn kii fi jẹ́ kí obìnrin jẹ Ọ̀ọ̀ni ni Ile Ife
Femi Babalola sọ nipa bi oun ṣe n lo ọpọlọ fi ṣe iṣẹ ọna to wu u.
O n i inu Baba oun ko kọkọ dun si iṣẹ naa ti oun n ṣe.