E jẹ́ ká lọ sí ìlú mi BBC yìí dá lórí Epe ní bi tí eégún ti ń fi ẹgba dá bírà lára Oba
Wa mọ sii nipa Epe Ijebu ati Epe Eko
Eto ẹ ka lo si ilu mi ni ilu Epe ni BC Yoruba gbe wa lọsẹ yii.
- 'Restructuring' la fi ta Buhari fún ìran Yorùbá, ṣùgbọ́n ó dùn mi pé irọ́ ni Buhari pa- Olagunsoye Oyinlola
- Títí di bí a ṣe ń sọ̀rọ̀ yìí, èmi gan an kò mọ irú ẹni tí Wole Soyinka jẹ́- Ojọ̀gbọ́n Wole Soyinka
- Ṣé ìwọ mọ ìtàn Ọdẹ tó tẹ Ẹ̀pẹ́ dó láti ìgbà ìwásẹ̀?
- Mọ̀ síi nípa Ibeju Lekki nípinlẹ̀ Eko níbí tí wọn kò tí ní iná Mọ̀nàmọ́ná fún ogún ọdún tí Bàálẹ̀ ti ń fa 'Generator'
- Ó kéré tán, ajínigbé ti pa èèyàn 222 láàrìn oṣù mẹ́ta ní Kaduna- Gomina El Rufai
- Ṣé ìwọ mọ ìtàn Ọdẹ tó tẹ Ẹ̀pẹ́ dó láti ìgbà ìwásẹ̀?
Epe lo ni ẹja ati awọn ẹranko omi to pọ ni jijẹ.
Wo oríṣi ẹja tó kún ìlú Epe ní ìpínlẹ̀ Eko.

Se ẹ ranti ayaba Sheba tó ṣabẹ̀wò sí Oba Solomoni nínú Bibélì?

Wo ibi tó gbé ní Epe rí kó tó lọ sí Oke Ẹri ní Ijẹbu Ode.

Waheed Agbomeji sọ itan bii Bilikisu ṣe gbe ni Epe.
Alahji Waheed salaye kikun lori bi o ṣe kuro ni epe ati awọn ibi to tun lọ ki ọlọjọ to de.

Wa mọ ipa ti Oba Kosoko ko nipa itan Epe
Wo awọn Oba to ti jẹ ni Epe.

Oba Shefiu Olatunji Adewale pa itan bi Epe ṣe bẹrẹ bẹẹ ẹnu agba lobi ti n gbo.

Oba Olufolarin Ogunsanwo ti Ilara Epe salaye ipo pataki ti alara n ko ninu itan Epe.

Bakan naa ni Ooni Adeyey Enitan Ogunwusi mẹnuba itan Ilara mokin, Ilara moko ati Ilara Epe .

O so nipa odu Ogbe Alara to jẹ Ogbe Iyeku meji to da wọn silẹ pẹlu adura.

Wo igbesẹ inu ọdun Kilajolu nibi ti eegunti n na Kabiesi ko to gabdura fun ara ilu.

- Buhari fẹ́ dá Naijiria padà sí ọdún 1984, ṣùgbọ́n a kò ní gbà fun- Femi Falana
- Ọwọ́ àjọ NDLEA tẹ ògbóǹtagì oníṣòwò òògùn olóró méje
- Olubunmi Afuye: Ohun táa mọ̀ nípa akọ̀ròyìn tó kàgbákò ikú lọ́wọ́ Adigunjalè tó fọ́ Báńkì l'Ondo
- Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa "food poisoning" àti bí o ṣe lè dẹ́kun rẹ̀
- Akeredolu, NUJ àtàwọn míì ń ṣèdárò Bunmi Afuye tó bá ìṣẹ̀lẹ̀ ìdigunjalè lọ l'Ondo
- Ẹ wo ibi ọ̀rọ̀ dé dúró lórí àwọn afurasí tó lọ́wọ́ nínú ikú Tolulope Arotile