Coronavirus survivor: Kòkòrò coronavirus sì wà lára mi títí mo fi kúrò ní ibùdó ìtójú àwọn alárùn covid-19
Ọkan lara awọn eeyan to ti la ewu ajakalẹ aarun coronavirus nilu Eko, l’orilẹ-ede Naijiria, Motosinoluwa Afolaranmi, sọ iriri rẹ fun BBC News Yoruba.
O ṣalaye pe lati oru ọjọ ti awọn eleto ilera ti wa gbe oun kuro nile, ni awọn eeyan ti mọ pe oun ni aarun naa, nitori pe ẹnikan ya fidio oun lasiko ti wọn wa gbe e, o si fi si ori ayelujara.
O sọ pe igbeaye ko ri bakan naa mọ lati igba ti oun ti pada sile, nitori pe awọn ara adugbo n dẹyẹ si oun.
Bakan naa lo sọ pe ijọba n gbiyanju lori amojuto aarun naa ni Naijiria, ṣugbọn omi ṣi ku lamu.
Ẹkunrẹrẹ ọrọ wa ninu fidio naa.
- Òṣèré tíátà, Ọmọba Femi Oyewunmi tí ọ̀pọ̀ mọ̀ sí Laditi ti jáde láyé
- Ọ̀nà mi dàrú nígbà tí wọ́n lé mi ní Fáṣitì Ilorin, ọpẹ́ ádúrótì ìyá mí - Agba Inaki
- Ìrírí àwọn ọ̀dọ́ ilẹ̀ Áfíríkà tó ń wá ìgbé ayé rere lọ sí Yúróòpù
- Àjọ NAFDAC ti bẹ̀rẹ̀ àyẹ̀wò àgbò mẹ́rin tí wọ́n ṣe ní Nàìjíríà fún Covid-19
- Kíni ìjọba ń ṣe lórí ewu ẹkọ Almajiri àti covid 19 ní Nàìjíríà?