Tọkọ-tayà kọ ara wọn silẹ nitori Buhari nínú ìdìbò 2019 tó m bọ̀ Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àkọlé àwòrán, Ko yẹ ki igbeyawo tuka nitori idibo 2019 24 Sẹ́rẹ́ 2019
Abdullahi ṣalaye fun BBC pé oun ti kọ iyawo oun silẹ lataari pe ó fe ki Buhari tun wọle ni 2019.
Awọn mejeeji gbéná wojú ara wọn ninu ilé nigba ti ọkọ sọ pe o dara ki Buhari maa ṣe ijọb alọ ti iyawo dẹ ni rara, eyi ti Buhari ṣe to, ko pada si Daura.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "BBC Yoruba ń pè yín sí ìpàdé ìtagbangba", Duration 0,51 00:51 Àkọlé fídíò, ìpàdé ìtagbangba ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn olùdíje sípò gomina ní ìpínlẹ̀ Eko. Abdullahi ni oun ti fibinu ká eyin lẹnu iyawo kí iroyin ija naa to kàn dé ọdọ awọn obi oun.
Oríṣun àwòrán, Getty Images
Àkọlé àwòrán, Ohun to ṣe pataki julọ ni ki olori sẹ ohun to yẹ fara ilu Gbogbo igbiyanju BBC lati bá Hafsat sọrọ lori iṣẹlẹ yii ja si pabo nitori wọn ni o n gba itọju.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "Day 23: Ikẹnnẹ ṣááju àti lẹ́yìn ìwọlé Ọṣinbajo sípò #BBCNigeria2019", Duration 4,37 04:37 Àkọlé fídíò, Osinbajo: Ikẹnnẹ yẹ kó jẹ́ Mẹ́kà òṣèlú ni Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "Exclusive: Tí a bá gbé ẹ̀ṣẹ̀ àwọn tó ń ṣèjọba lọ́wọ́ jáde, wọn yóò wọná - Obasanjo", Duration 9,25 09:25 Àkọlé fídíò, Obasanjo: Atiku kìí se Áńgẹ́lì, àmọ́ yóò se dáadáa ní ìlọ́po méjì ju Buhari lọ Ibatan rẹ, Ibrahim Suleiman ti BBC ri ba sọrọ ṣalaye pé ọkọ iyawo ti fẹsẹ fẹẹ lẹyin iṣẹlẹ yii ati pe, o ti ni oun kò ni pada sile mọ.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "Wọ́n fi iṣẹ́ tàn ań wá sí Eko, kí wọ́n tó fun ní HIV", Duration 5,12 05:12 Àkọlé fídíò, Ọ̀tọ̀ ni nkan tí wọ́n sọ fún ẹbí rẹ̀, iṣẹ́ aṣẹ́wó ni wọ́n fi n ṣe O dabi pe idibo 2019 maa bi ige ati adubi nitori onikaluku lo ni idi to fi n ṣatilẹyin fawọn oludije ọtọọtọ paapaa ninu idle kan ṣoṣo.
Ati pe eyi wu mi, ko wu ọ ni ọrọ naa di bayii laarin ẹbi lori awọn amuyẹ oludije kọọkan.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "Day 24: Ǹjẹ́ O lè dìbò fún ẹni tí àlùfáà tàbí ìmámù rẹ́ bá yàn?#BBCNigeria2019", Duration 3,51 03:51 Àkọlé fídíò, 2019 Elections: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò Bẹẹ, awọn iṣẹlẹ bayii ni awọn mii gba pe o n waye nitori pe awọn oludije mejeeji to n léwájú wa lati agbegbe kan naa ni ariwa Naijiria.
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
Play video, "Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja", Duration 1,00 01:00 Àkọlé fídíò, Murphy Elégungun Rọba: Mo fẹ́ di ẹnití egungun rẹ rọ jùlọ ní àgbáyé