Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́

Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 2

Ọrọ o maa tii tan lori ida aadọta afikun owo tariifu ipe ati data

Ki lo tun ṣẹlẹ o, ṣo ti walẹ ni?

Rara o! Ẹgbẹ oṣiṣẹ NLC lo kede pe awọn ṣetan lati ṣewọde tako àfikún owo ipe ati data

T'ijọba ko ba paṣẹ idaduro afikun owo naa

Lọjọ wo wa ni iwọde naa yo waye?

Alaye wa lori BBC.Com/Yoruba

''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Irọ nla lẹgbẹ APC n pa, Rauf Aregbesola, lo kuro ninu ẹgbẹ funra rẹ

Alukoro ẹgbẹ Omoluabi nipinlẹ Osun, Abosede Oluwaseun ti fidi rẹ mulẹ pe

ahesọ ọrọ lẹgbẹ oṣelu APC sọ pe awọn lo le gomina ipinlẹ Osun tẹlẹ kuro ninu ẹgbẹ naa

ẹgbẹ oṣelu wo ni Aregbe wa fẹ darapọ bayii?

Kan soju opo BBC.Com/Yoruba fun esi ibeere rẹ

'''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''''

Awọn oṣiṣẹ adoola ẹmi ti sọ pe o ṣee ṣe ki gbogbo ero

Inu ọkọ baalu meji to fori sọra wọn ni Washington lalẹ Ọjọru ba iṣẹlẹ naa lọ

ikọ adoola ẹmi ti sawari oku eeyan mọkandinlogun to ja latinu baalu naa sinu odo

Fun ẹkunrẹrẹ iroyin yii