Ayodeji Rotinwa ni ìròyìnn òfegè gbé àwòrán rẹ̀ síta pè dókítà tó ń pa àwọn Hausa mùsùlùmí

Àkọlé fídíò, Ayodeji Rotinwa ni ìròyìnn òfegè gbé àwòrán rẹ̀ síta pè dókítà tó ń pa àwọn Hausa mùsùlùmí

Ayodeji Rotinwa ni ọdọmokunrin kan ti aworan rẹ lu ori ayelujara pa laipe

Nibẹ ni wọn ti sọ pe oruko re ni Christopher Uche Ayodeji.

Leyin ti awọn alakatakiti ẹsin Islam kan dana sun Deborah Samuel to jẹ akẹkọọ ile ẹkọ olukoni Shehu Sagari ni ipinlẹ Sokoto ni iroyin naa jade.

Ayodeji Rotinwa salaye pe oun ko tile sise dokita ri de ibi pe oun a nile iwosan lati fi maa pa awọn musulumi ti won wa lati eya hausa rara.

O ni akoroyin ni iṣẹ ori ran oun ti oun de n ṣelati ibẹrẹ aye oun titi di oni yi.

Ayodeji salaye pe lati igba naa ni oun ti sakuro nile to n gbe to si n sa asala fun emi ara rẹ latari iroyin ofege ti wọn pa mọ oun.