Babangida: Èròǹgbà ọmọ Nàíjíríà pọ̀ èyí tó ṣòro láti bá pàdé

Oríṣun àwòrán, Twitter/Presidency
Olori orilẹede Naijiria tẹlẹ ri, ajagunfẹhinti Ibrahim Babangida ti ṣapejuwe Naijiria gẹgẹ bi orilẹede to ṣoro lati dari.
Babangida fọrọ yii lede lasiko tawọn alaṣẹ ẹgbẹ oṣelu PDP kan sii nile rẹ niluu Minna, ni ipinlẹ Niger.
Babangida tun lo anfani naa lati kepe awọn aṣofin gbọdọ ṣiṣẹ takuntakun lati rii wi pe orilẹede Naijiria wa ni iṣọkan.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Èmi àti Saheed kìí ṣe ọmọdé, a ti jọ ṣe Sinimá papọ̀, èyí túmọ̀ sí pé ìjà ti parí - Fathia Balogun
- "Mo fẹ́ pa ara mi torí ojú àbùkù tí wọn ń fi wò mí pé mo fi iṣẹ́ abẹ bímọ"
- Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho
- Ọjà Àgbáláta ní Badagry rèé, níbití ẹran ejò ti dùn ju ẹran adìẹ lọ
- Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ nkan tó wà láàrin èmi àti Ireti Ajanaku - Tope Alabi
O ṣalaye pe, gbogbo ohun to n ṣẹlẹ ni Naijiria ni oun n fi ọkan ba lọ, to si gbe oṣuba kare fawọn alaṣẹ ile igbimọ aṣoju ṣofin l'Abuja, adari ile ati gbogbo ile lapapọ.
O rọ wọn wi pe, ki wọn maa kaarẹ ninu akitiyan lati ri wi pe Naijiria toro, nitori oriiṣiriiṣi erongba lawọn ọmọ Naijiria ni eyi to jẹ ko ṣoro fun awọn alaṣẹ lati dari.
- Ẹ sọ èdè Yorùbá kíkà di kàńpá níléẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ̀rẹ̀ àti girama - Ẹgbẹ́ Akọ́mọlédè
- A ò ní fààyè gba pípa ọmọ Naijirià nípakúpa ní South Africa mọ- Abike Dabiri
- Busola Daakolo: Mi ò fọwọ́ sí ìwé kankan tó takò ẹ̀sùn tí mo fi kan Fatoyinbo
- Sowore takú, kò jẹun ní àgọ́ ọlọ́pàá torí májèlé - Deji Adeyanju
- Owó dé! Akẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ òfin kọ̀ọ̀kan yóò gba ₦500,000 owó ìrànwọ́ l‘Oyo
Babangida fun wọn ni idaniloju pe, oun wa pẹlu wọn ninu igbesẹ wiwa ilọsiwaju fun orilẹede Naijiria.
O tun gba wọn nimọran pe, ki wọn mase gbagbe lati mu awọn ileri ti wọn ṣe fawọn to dibo yan wọn lẹkun ti wọn n ṣoju sẹ, nibayii ti wọn ti wa nile aṣofin l'Abuja.








