Buhari gbọ́dọ̀ yọ àwọn mínísítà tí kò wúlò ní sáà kejì yí-Ogundamisi
Lori ifilọlẹ saa isejọba to n bọ, onwoye nipa ohun to n lọ lawujọ naa ni Buhari yẹ ko yọ awọn oloye rẹ ti ko ba sisẹ bo se yẹ nipo, ko si fi awọn eeyan to da loju pe wọn yoo sisẹ kara sipo.
Ogundamisi tun ni isẹ ti isejọba Buhari se laarin ọdun mẹrin pọ pupọ, amọ iroyin ati ipolongo nipa awọn akanse isẹ naa mẹhẹ pupọ.
- Ó tó gẹ́, Atikulated àti àwọn àṣà ìpolongo tó gbòde lásìkò ìbò 2019
- Kamaru Usman: Ọmọ Áfíríkà àkọ́kọ́ tó gba ìgbànú ẹ̀yẹ ẹ̀ṣẹ́ kíkàn
- Ogun: Amosun, ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC fẹ́ forígbárí l'Ógùn
- Ìjọba pàṣán ni ìjọba Buhari yóò jẹ́ fún Nàìjíríà ní sáà kejì- Ṣoworẹ
- #BBCNigeria2019: Mo máa san ju #30,000 owó oṣù òṣìṣẹ́ tó kéré jùlọ ni Kwara- Issa Arẹmu
Kayọde Ogundamisi ni iṣejọba yii a so eso idagbasoke to yẹ ti aarẹ Buhari ba tete n gbe igbesẹ akin lori ọrọ awọn to n yan sipo laisko.
- Ẹgbẹ́ APC dá ọmọ Alao Akala padà sípò alága Ogbomọṣọ North
- Ọjọ́ Àbámẹ́ta la ó mọ ẹni tí yóò lékè láàrín bàbá ìsàlẹ̀ àti àwọn mẹ̀kúnnù nipinlẹ̀ Ọyọ. – Seyi Makinde
- 2019 Elections: NBC na Channels TV àti ilé iṣẹ́ ìròyìn 44 ní pàsán
- Ètò tí mo ní fún Kwara yàtọ̀ sí ti ANRP ni mo ṣe fẹgbẹ́ wọ́n sílẹ̀ - Yinka Ajia