Niger Flood: Omíyalé àgbàrà ti ya ṣọ́ọ̀bù ní Niger

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Bi ojo ṣe n rọ lasiko yii ni orilẹ-ede Naijiria ti ẹru omiyale n ba awọn eniyan bẹẹ naa ni ojo naa n rọ ni orilẹ-ede Niger.
Ojo arọọroda to rọ ni ọjọ kẹta, oṣu kẹsan an ọdun yii lo n jẹ ki ọkan awọn obinrin yii ma balẹ ni agbegbe Kirkissoye ni Niamey.

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Orọ omiyale agbara ya ṣọọbu yii ko yọ awọn ọdọmọde silẹ ni Naimey.
Awọn naa lọ n gbọ́n iyẹpẹ fi di awọn ibi ti omu ti gba opopona to si ti n ya wọnu ile.

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Awọn oṣiṣẹ ileeṣe panapana ni orilẹ-ede Niger ti ko awọn eniayna kuro ni Niamey to jẹ olu ilu Niger.
won ko won lọ si ibudo ti omi ko pọ si .

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Ara agbegbe Kirkissoye kan ni yi ni Niamey to n wo ile rẹ ti omi ya wọ ti ko si si nkan to le ṣe.

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Oríṣun àwòrán, Getty Images

Oríṣun àwòrán, Getty Images
Akọsilẹ to peye ni wọn n ṣe fun ohun to nilo ati awọn to yẹ fun ipese fawọn to lugbadi omiyale.














