Àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀èdè Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí Nàìjíríà

Àkọlé fídíò, Àwọn ọ̀dọ́ orílẹ̀èdè Nàìjíríà sọ èrò wọn lórí Nàìjíríà

Owe agba lo sọ pe Oriṣa ti baba ba sin ti ko fi han ọmọ, kii pẹ parun.

Awọn ọdọ orilẹede Naijiria ti pari sita pe awọn naa ni ọrs lati sọ o. Idi gan niyi ti BBC News Yoruba fi gbe wọn wa si gbagede ọrs lori bi nnkan ṣe n lọ lorilẹede Naijiria ati ero wọn lori

rẹ.