Ìjọba Èkó: Àdínkù yóò wà fún ìgbòkègbodò ọkọ̀ ní Agége

Oríṣun àwòrán, Lagos State Govt/Twitter
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó tí kéde pé òun yóò túbọ̀ mú adinku bá igbòkè gbodo ọkọ̀ lágbègbè Pen Cinema.
Ìjọba kéde ọ̀rọ̀ òhún nínú àtẹ̀jáde kan tí akowe àgbà ilé ìṣẹ̀ Irina gbé jáde, pé ìgbésẹ̀ yìí yóò fún ìjọba láǹfààní láti parí afárá Pen Cinema lásìkò tó yẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Àwọn òṣìṣẹ́ àjọ UN sọnù
- Ààrẹ Buhari tẹkọ̀ òfurufu létí lọ sí America
- Ǹkan tí ẹ kò mọ̀ nípa olóògbé AdéyemọÓ ní oríta Agége láàárín isọdá Raluwe sì Church street ni yóò kan julọ, fún ìdí èyí Akowe àgbà náà sọ pé, àwọn ọkọ tó ń bọ̀ láti Ipaja lọ sí Ọgbà kò ní láǹfààní láti ya si Òkè-KòtòÓ rọ àwọn awako tó ń bọ̀ láti Abúlé Ẹ̀gbá láti gba Oko-Oba jáde si orileÌjọba ro awon ara ìlú láti ni suuru fáwọn adari ọkọ àti àwọn ẹsọ alaabo lójú pópó.








