Akure Oloyemekun: Ṣé ẹ ti gbọ́ nípa Ua Agbeto rí níbí tí ìtọ̀ kìí rùn bó bá ṣe pọ̀ tó?
Ṣé ẹ ti gbọ awọn itan kankakanka nipa iṣẹdalẹ ilu Akurẹ?
BBC Yoruba ba eeyan ilu Akure rinrinajo lọ si ilu nla naa koda to fi mọ awọn kọrọ ilu Akure.
A ni ifọrọwerọ pẹlu Deji, Ọba ilu Akure to sọ idi ti gbogbo Ọba ilu Akurẹ fi n jẹ Déjì lái ṣe Alakurẹ.
Ọna kan wa ninu aafin Deji Akure to ṣe pataki leyi to jẹ wipe ẹẹkan ṣoṣo ni Kabiyesi lee gba ibẹ ni igbesi aye rẹ to jẹ pe igba to ba ṣẹṣẹ jba ti wọn a mu u wọ inu aafin.

Ṣe ẹ tun ti gbọ nipa ibi iṣẹmbaye to n jẹ Ua Agbetọ nibi ti ẹ o le gbọ oorun itọ kankan ko si bi ọgọọrọ eeyan ba ṣe tọ sibẹ to.
Ẹ ba wa kalọ ninu fidio yii si awọn ibi kọlọfin ati ibi gbangba ilu nla nni, Akurẹ.

- Ohun tí ìyàwó Adeboye ṣe ní ìgbà akọkọ tó fojú hàn lẹ́yìn ikú ọmọ wọn Dare
- A furasí pé àwọn kan mọ̀ọ́mọ̀ sọ iná sí Ọ̀já aṣọ Kairo l'Oshodi - LASEMA
- Ọmọ Nàíjíríà sọ̀kò ọ̀rọ̀ síjọba lórí èròǹgbà láti dín owó oṣù òṣìṣẹ́ kù
- Àwọn ǹkan tí o kò gbọ́ rí nípa Dare Adeboye tó kú
- Ẹ tú Baba Ijesha sílẹ̀ pẹ̀lú Béèlì, ẹ má ṣi agbára òfin lò bí bẹ́ẹ̀ kọ́

