Bí àlááfíà yóò ṣe wà láàrin Fulani àti Yorùbá ni Ooni bá lọ sọ́dọ̀ Buhari- Ààfin Ile Ife
Aafin Ile Ife ti ṣalaye idi abajọ ti Ooni Ile Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi fi ṣabẹwo si Aarẹ Muhammadu Buhari lori aawọ to wa laarin awọn Fulani atawọn agbẹ nilẹ Yoruba.
Agbẹnusọ fun Ooni, Moses Olafare sọ fun BBC Yoruba pe Ooni sọ fun Buhari lati wa nkan ṣe si ọrọ awọn Fulani kan to huwa ọdaran nilẹ Yoruba ni.
Ọgbẹni Olafare fikun ọrọ rẹ pe Ooni gbọingbọin ni Kabiyesi wa lẹyin Sunday Igboho, amọ ọba laye gbọdọ pẹtu si ija ni nitori ko si ọba to maa fẹ ki ilu tu mọ ọ lori.
Ọlafare ko ṣai kilọ fun Igboho pe ki ijimere rẹ ṣogi gun, ko maa ba gun igi aladi.
- A kò kórira àwọn Fulani, àwọn ọ̀bàyéjẹ́ ìnú wọ́n ni á kò fẹ́ - Ọba Akintunde ni ẹkùn Yewa, ìpínlẹ̀ Ogun
- Ọlọ́pàá Ogun ké pe ẹni tó ni Pavillion Hotel láti wá ṣàlàyé ìdí tí kámẹ́rà fi wà nínú yàrá
- Irọ́ ní o, a kò buwọ́lu Goodluck Jonathan fún ipò ààrẹ 2023 - APC
- Bàbá mi Ooni, ẹ foríjìn mí, ẹnu mi ò gbàá láti bú yín- Sunday Igboho tọrọ àforíjìn
- Ènìyàn 1,138 tún ti lùgbàdì ààrùn Covid-19 ní Nàijíríà
- Èrò àwọn eèyàn ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí iléẹ̀kọ́ Gbogbonìṣe tuntun tí Buhari ní kí wọ́n dá sílẹ̀ ní Oyo