Rape: Oríṣí ìjìyà ní àwọn bíi Gómìnà El Rufai àti Fayemi ń bèèrè f'àwọn afipábánilòpọ̀
Nibo ni ọrọ ile aye n lọ bayii lori ifipabanilopọ?
BBC Kayeefi oṣu kẹfa yii lọ si Ado Ekiti nibi ti ọmọbinrin kan ti wọn fipa ba lopọ loke ọja ti ṣe iranlọwọ fun awọn agbofinro ti ọwọ si tẹ awọn ọdọmọkunrin oniṣẹ ibi naa.
Kọmiṣọnna ọlọpaa ni ipinlẹ Ekiti, Amba Asuquo kilọ fun awọn obi lati mojuto awọn ọmọ wọn obinrin to n kiri ọja.
Bakan naa ni awọn eeyan ati ajafẹtọ ọmọniyan sọ iriri wọn lori ifipabanilopọ ni eyi ti o yẹ ki gbogbo awujọ fọwọsowọpọ gbogun ti lasiko yii.
- Ìyá àádọ́rin ọdún sọ bí ọkùnrin ọdún márùndínlọ́gbọ̀n ṣe fipá bá òun lòpọ̀
- Ẹ wo ìṣẹ̀lẹ̀ nípa ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ tí wọ́n fi kan D'banj ní sísẹ̀-n-tẹ̀lé
- 'Màálù tó bá tàsẹ̀ àgẹ̀rẹ̀ níwájú ilé mi, ó dẹran àsun!"
- Omijé bọ́ níbi ìsìnkú Ogun Majek
- Eji Gbadero, ọmọ Ibadan àti jayé-jayé ọmọ ónílẹ̀ ti wọn yẹgi fun l'Eko