May 29: Akala, Aleshinloye sọ̀rọ̀ lórí ọdún kan Seyi Makinde gẹ́gẹ́bíi gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Ni oni, ọjọ kọkandinlọgbọn oṣu karun un, ọdun 2019 ni wọn bura fun Seyi Makinde gẹgẹ bi gomina ipinlẹ Ọyọ lẹyin to bori ninu ibo ọdun naa.
Ọdun kan lẹyin eyi, BBC News Yoruba gbe ọrọ tọ awọn eekan oloṣelu ni ipinlẹ naa lọ lati mọ ero wọn lori ijafafa iṣẹ iṣejọba ni ipinlẹ Ọyọ.
Abọ ree.
- Ó ṣeéṣe kó jẹ́ pé àwọn alágbara ló ń fi agbára hàn lórí arábìnrin tó fẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀ kan kọmíṣọ́nà Kogi -Agbẹjọ́rò
- ₦22.5M ti pọ̀ jù fún owó fọ́ọ̀mù ìdìbò abẹ́lẹ́ sípò gómìnà APC - SERAP
- N4,200 la fẹ́ fi pèsè oúnjẹ fún akẹ́kọ̀ọ́ kọ̀ọ̀kan láti ìdílé tó lé ní mílíọ̀nù mẹ́ta yíká Nàìjíríà - ìjọba àpapọ̀.
- Ìtàn ìgbésí ayé Oshodi, ọmọ Tápà léǹpe tó di akọni ní ìlú Eko
- Ǹjẹ́ o mọ àwọn òṣèré bí Oyin Adejọbi, Funmi Martins àtàwọn míì tó ti dágbére fáyé?
- Makinde ni gómìnà, èmi ni igbákejì rẹ̀; kò sí ìjà láàrin wa-Rauf Adeniyan, igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
- Ṣọ́ọ́ṣì kan sí ìlẹ̀kùn rẹ̀ fún àwọn mùsùlùmí láti kírun Jímọ̀ ní Germany
- Mo wọ bàtà àti fìlà wọ pẹpẹ Cele láti ṣe wáàsí, kò sí ṣọ́ọ̀ṣì tí n kò le wọ̀ - Sheik Buhari ọmọ Musa