Balogun market fire: Olubadamọran gomina sọrọ lori ina náà
A ko ni akiyesi ina ni Naijiria bii tawọn eeyan ilẹ oke okun- Kehinde Ajikande
Lẹyin ti ọja Balogun tun jona ni ipinlẹ Eko ni awọn oniṣowo loriṣiirisi ti n fi ero ọkan wọn han lori iṣẹlẹ naa.
Oriṣii ọna ni awọn eeyan mii n gba tumọ iṣẹlẹ ọja jijona naa ti wọn lo maa n ṣẹlẹ lọdọọdun.
Ọpọ gba awọn oniṣowo ninu ọja yii lo ti ni ki ijọba wadii iṣẹlẹ ina naa bo ti yẹ ki iru rẹ le dopin.
Wọn tun sọrọ lori adanu nla ti awọn ọlọja n koju gegẹ bii ipenija wọn.
- Ọ̀gẹ̀dẹ̀ ń bàjẹ́..; Akẹ́kọ̀ọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ 12 gbà èèyàn láti kọ ìdánwò fún wọ́n
- Òògùn tọ́jọ́ fẹ́ lọ lórí wọn ni àjọ SACA ń rà lábẹ́ àkóso aya Ajimobi - Seyi Makinde
- Bí alárùn Ebola bá wọ Nàíjíríà, kò sí gìrì, a ti múra sílẹ̀ láti paná rẹ̀ - Àjọ NCDC
- Ó ṣe jẹ́ ṣọ́ọ́bù aláṣọ kanṣoṣo ni iná tí maa ń ṣẹ́yọ lọdọọ́dún lọ́jà Balogun?
Olanrewaju Elegushi to jẹ olubadamọran fun gomina Sanwo Olu to n tukọ ipinlẹ eko ṣalaye pe asiko ti to ki ijọba ati ara ilu tubọ maa fiyesi iṣẹlẹ ina ojiji.
Igbiyanju BBC lati ba awọn ti ọrọ kan lori ọrọ aajo aje yii sọrọ ja si pabo.
- Olujinmi ló borí ìbò fẹ́kùn gúúṣù Ekiti, Adeyeye gba ile lọ - Iléejọ́ Kòtẹ́milọ́rùn ṣèdájọ́
- Osinbajo kìí ṣe amúgbálẹ́gbẹ̀ẹ́ Buhari tí yóò máa gbé ìwé lọ fun ní London - Akin Alabi
- Ẹ̀yin òbí, ẹ má kó àwọn ọmọ yín lọ síbùdó atúnwàṣe mọ́ - Seyi Makinde
- 'Ǹkan tó jẹ́ kí iṣẹ́ ọ̀nà tèmi yàtọ̀ lágbàáyé ni ǹkan tí mò ń lò'