Coronavirus in Nigeria: Ǹjẹ́ ṣé òògùn apakòkòrò le pa ààrùn coronavirus?
Oriṣiiriṣii nnkan lawọn eeyan n sọ pe o le wo aarun coronavirus ti o ba gbogbo aye finra lọwọ.
Laipẹ yii ni aarẹ orilẹede Amẹrika sọ oogun apakokoro pe o le wo aarun aarun coronavirus.
Ko si ohun to jọ bẹẹ raa! Ajọ eto ilera lagbaye, WHO sọ pe iwadii si n lọ lọwọ lori ati wa oogun tabi abẹrẹ to le wo coronovirus ṣugbọn ko sii oogun rẹ bayii.
Alaye lẹkunrẹrẹ fidio yii.
- Àwọn èèrò ìwòran ní kóótù gbalé ẹjọ́ dọ́gbà ẹ̀wọ́n l'Ọṣun
- Wo àwọn ọmọbìnrin tó mu ìtọ̀ ara wọn nítorí òùngbẹ aṣálẹ̀ Sahara
- 'Dokita ilé ìwòsàn ló gba ẹsẹ̀ lọ́wọ́ mi'
- Ǹjẹ́ òògùn vitamin C lè pa coronavirus?
- Ǹjẹ́ ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus?
- Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu
- Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek
- Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
- Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC
- Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus