Coronavirus: Irọ́ ńlá ni pé ewé dongoyaro lè wo aàrùn coronavirus
Lẹyin ti arun Coronavirus di tọrọ fọnkale lọpọ orilẹede kaakiri agbaye, ọpọ awọn eeyan lo n sọ lori ayelujara pe ewe dongoyaro le wo aarun coronavirus.
Ko si ohun to jọ bẹẹ rara! Gẹgẹ bi ọrọ ti ajọ to n risi eto ilera lagbaye, WHO ṣe sọ, ewe dongoyaro ko le wo aarun covid-19.
Ajọ WHO ṣalaye pe ko tii si oogun tabi abẹrẹ to le wo aarun coronavirus lọwọlọwọ bayii.
Ajọ naa ni ewe dongoyaro ko tiẹ le ṣe adinku aarun naa lara alaisan.
Bi ọrọ ṣe jẹ wa ninu fidio yii.
- Ìyàwó mi ṣẹ̀ṣẹ̀ bímọ tuntun, kò si oúnjẹ fún wa torí ìgbélé Coronavirus- Yakubu
- Auxiliary lo ń jà káàkiri ìlú Ibadan lọ́jọ́ Aje, ẹgbẹ́ ọlọkọ èrò NURTW kọ - Ejiogbe
- Coronavirus ló lé mi kúrò níléèwòsàn UCH n'Íbàdàn- Ogun Majek
- Ta a ni yóò rọ́pò Abba Kyari gẹ́gẹ́ bi olórí òṣìṣẹ́ Buhari?
- Àṣìṣe ló ṣẹlẹ̀ níbi ètò ìsìnkú Abba Kyari- FCTA
- Yewande bí'mọ tuntun jòjòló, Mercy Aigbe pàdánù èèyàn rẹ̀, Toyin Abraham fèsì lórí aṣoju NCDC
- Ìtàn Manigbagbe: Àwọn àjakalẹ-àrun to ti wáyé rí ṣáájú Coronavirus