Àwọn àwòrán tó jẹ ojú ní gbèsè láti ibi ìwúyè Aláàfin Abimbola Owoade

Alaafin Abimbola Akeem Owoade I
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 3

Ọjọ Abamẹta, ọjọ karun un, oṣu Kẹrin, ọdun 2025, jẹ ọjọ manigbagbe ni ilẹ Yoruba, paapaa julọ, ilu Oyo.

Eyi ko ṣẹyin bi ọba tuntun, Alaafin Abimbola Akeem Owoade I ṣe gun ori apere awọn baba nla rẹ.

Eyi waye lẹyin ti Ọba Lamidin Adeyemi III waja lọdun 2022.

Alaafin Owoade ni Alaafin Kẹrindinlaadọta to jẹ niluu Oyo.

Akojọpọ diẹ ree lara bi ayẹyẹ iwuye naa ṣe lọ, ninu aworan.

Alaafin Owoade ati olori rẹ,
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, naa darapọ mọ awọn eeyan nlanla to pejọ sibi iwuye Alaafin tuntun, Ọba Abimbola Akeem Owoade
Àkọlé àwòrán, Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, naa darapọ mọ awọn eeyan nlanla to pejọ sibi iwuye Alaafin tuntun, Ọba Abimbola Akeem Owoade
Gomina ipinlẹ Oyo, Seyi Makinde, naa darapọ mọ awọn eeyan nlanla to pejọ sibi iwuye Alaafin tuntun, Ọba Abimbola Akeem Owoade
Ooni Ile-Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi naa wa ni ikalẹ lati dawọ idunnu pẹlu Oba Owoade I
Àkọlé àwòrán, Ooni Ile-Ife, Ọba Adeyeye Enitan Ogunwusi naa wa ni ikalẹ lati dawọ idunnu pẹlu Oba Owoade I
Awọn to n jo ijo ibilẹ
Àkọlé àwòrán, Aṣọ n pe aṣọ ran niṣẹ, bẹẹni oriṣiriṣi ijo ati afihan aṣa Yoruba naa ko gbẹhin nibi iwuye naa
Sultan ilu Sokoto
Àkọlé àwòrán, Sultan ilu Sokoto, Muhammadu Sa'ad Abubakar, naa ba wọn kopa nibi ayẹyẹ nla naa
Soun ti Ogbomoso, Oba Ghandi Olaoye
Àkọlé àwòrán, Awọn ọba alade naa ko gbẹyin nibi iwuye ọhun. Lara awọn oriade to tun peju sibẹ ni Soun ti Ogbomoso, Ọba Ghandi Olaoye
Ọba Abimbola Owoade I
Àkọlé àwòrán, Alaaafin tuntun, Oba Abimbola Akeem Owoade I ree, to gunwa ninu ọla nla rẹ gẹgẹ bi ọba
Alaafin Owoade ati olori rẹ, Ayaba Abiwumi Owoade
Àkọlé àwòrán, Alaafin Owoade ati olori rẹ, Ayaba Abiwumi Owoade
Awọn to n lu ilu
Àkọlé àwòrán, Oriṣiriṣi ilu ilẹ Yoruba ni wọn lu nibi ayẹyẹ naa
Olori awọn ẹya Igbo nilẹ Yoruba
Àkọlé àwòrán, Iṣọkan dun pupọ! Olori awọn ẹya Igbo nilẹ Yoruba, naa ba wọn peju sibi ayẹyẹ iwuye naa
Yemi Elebuibon
Àkọlé àwòrán, Araba ilu Osogbo, Oloye Ifayemi Elebuibon naa ba wọn kopa nibi ayẹyẹ nla naa
Oluwo ti Iwo
Àkọlé àwòrán, Oluwo ti Iwo, Oba Abdurasheed Akanbi naa ko gbẹyin nibi ayẹyẹ manigbagbe ọhun
Gani Adams
Àkọlé àwòrán, Aarẹ Ọna Kakanfo ilẹ Yoruba, Oloye Gani Adams. Alaafin to waja laipẹ yii, Ọba Lamidi Adeyemi III, lo fi jẹ oye naa
Lara awọn alejo to kopa
Awọn eero nibi iwuye naa