Egungun Festival: Ẹ wo bí wọ́n ṣe ń ṣe ọdún eégún ní ìlú Benin Republic
Ọdun egungun jẹ ọkan lara awọn ọdun to wọpọ ni ilẹ Yoruba, to si ni igba ati akoko ti awọn eegun yii ma n jade lati ṣe ọdun wọn.
Eyi lo mu wa lọ si ilu Iyoko ni orilẹede Republic of Benin nibi ti awọn eniyan ti pejọ ni ọgọọrọ lati ṣe ọdun egungun.
Eegun alagbaa ni olori eeguin ni agbegbe naa, ti wọn si ni etutu ti wọn ma n ṣe fun gbogbo eegun to ba jade ki ilu le tuba, ki o si tuṣẹ.
- Àjọyọ̀ bẹ̀rẹ̀ ní Ekiti, Akure, Osogbo, Eko bí INEC ṣe kéde Bola Tinubu bíi ààrẹ Nàíjíríà tuntun
- Obidients àti àwọn yòókù, mo dúpẹ́ lọ́wọ́ gbogbo yín – Tinubu
- Ẹnì tó kàjú ipò Ààrẹ ló borí ìbò - Buhari
- Ayo Adebanjo tutọ́ sókè-fojú gbàá lórí èsì ìbò ààrẹ
- Wo ìtàn ayé Bola Tinubu tó di ààrẹ tuntun ní Nàíjíríà
Ẹ wọ ẹkunrẹrẹ fidio bi awọn eegun naa sẹ n dabira.