Fire Eater: Azonto ní àfojúṣùn òun ni láti lọ fi idán iná yìí pa owó lókè òkun
Ara ko ni tan nile alara ni Yoruba n sọ, airin jinna si ni airi abuke ọkẹrẹ.
Ina ti ọpọ eeyan maa n sa fun tori ọsẹ to lee ni se ni ọkunrin kan to n jẹ Timi, n jẹ bii ounjẹ, o fi n pa ara, to si tun n fi sere.
Lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ, ọkunrin naa ti inagijẹ rẹ tun n jẹ Azonto fikun pe oun lee fi omi lasan tan ina, bi o tilẹ jẹ pe awọn eeyan gba pe ina ati omi kii se ọrẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Èmi sì ní Oluwo tilẹ̀ Iwo, kò sí ìgbìmọ̀ ọba kankan tó lè ní kí ń rọ́ọ́kún nílé - Oluwo
- Toyin Abraham ọkọ rẹ̀ àti Ire ní London, Odunlade 'kòlábò' pẹ̀lú Mercy Aigbe
- Èlé owó iná ọba kọ́ ló kàn, ẹ kọ́ ṣàtúnṣe sí ìlànà àdánú tẹ́ ń ṣe fún wa - Iléeṣẹ́ apínná sọ fún ìjọba
- Àdínkù bá owó ojúmọ́ ọlọ́kadà l‘Ọyọ láti ₦200 si ₦100, owó gbígbà bẹ̀rẹ̀ lónìí
- A fẹ́ ìtọ́jú fún Boko Haram tó bá ronúpìwàdà, ẹ dá iléeṣẹ́ sílẹ̀ fún ìtọ́jú wọn - Ilé aṣòfin
- Olùkọ́ tó fi tipá gba ìbálé akẹ́kọ̀ọ́ tó fẹ́ wọ fásitì rí ẹ̀wọ̀n ọdún 21 he
- Fayose, o kò ní àmúyẹ gidi láti di ọmọ ẹgbẹ́ wa, àyè kò sí fún ọ - APC Ekiti
Azonto ni lasiko ti oun n sere itage ni oun kọ isẹ naa nipinlẹ Ogun, ti gbogbo eeyan si maa n pe oun ni Sango lai wa lati idile onisango tabi jẹ ọmọ ilẹ Yoruba.
Timi wa rọ yin kẹ mase fi ina sere nitori a kii dagba kọja ohun ti a ko ba mọ, ina si lewu.
Credit Joshua Akinyemi









