Tinubu ti ń gba orí ayélujára kan, àwọn aráàlú ń fèsì
Lori ibo to n bọ lọna lọdun 2023, ṣe lo da bii pe la ni ọdun ti a n sọrọ rẹ yii nitori bi awọn ọmọ Naijiria tagba tọmọde ṣe ko si sisọrọ nipa rẹ.
Eekan ninu ẹgbẹ oṣelu PDP ni Naijiria, oloye Bode George ba BBC Yoruba sọrọ lori eyi.
Bakan naa, George ni gbogbo ara oun loun fi gbaruku ti eto ẹṣọ alaabo Amotekun tawọn gomina ilẹ Yoruba ṣe agbekalẹ rẹ
Bode George ti oun naa fi igba kan ri jẹ gomina ologun ipinlẹ Eko sọ pe Amotekun yoo sọ aye dẹrun pẹlu eto aabo to mẹhẹ ni Naijiria bayii.
O ṣalaye ẹṣọ Amotekun ni o le wa ojutu si eto aabo to mẹhẹ nitori awọn lo mọ awọn to wa lagbugbo wọn.
- Ẹ̀ṣọ́ Amotekun ní láti ṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú ọlọ́pàá agbègbè- Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria
- Ó ṣeéṣe kó má sí ẹ̀ṣọ́ aláàbò Amotekun l‘Eko - Ìjọba Eko
- BBC Yorùbá pé ọdún méjì! Ẹ wò wá ẹ wo iṣẹ́ ọwọ́ wa
- Yàtọ̀ sí eku gọ́tà tàbí èku inú ilé, kò sí eku téèyàn ò lè jẹ - Òǹtajà Eléwé ọmọ
- Àwọn ọba tó wà lábẹ́ mi ń talẹ̀ nítàkutà- Oluwo
- Ibà Lassa wọ ìpínlẹ̀ Èkó!
- Ẹ̀yin òṣèrè tíátà, ẹ ní ṣùúrù de àsìkò Ọlọ́run, ẹ máṣe kánjú kọjá kádàrá - Madam Ṣajẹ
- Ọdọọdún làwọn ọmọ ònilẹ̀ ń dà wá láàmú ní Soka, kí Sunday Igboho tó gbà wá sílẹ̀ - Àwọn olùgbé Soka
Bode George ni abosi lo wa n bẹ ti ipinlẹ Eko ko ba ṣe Amọtẹkun lẹyin ti gbogbo awọn gomina ipinlẹ Yoruba yoku ti fọwọ si agbekalẹ eto naa.
Nigba ti o n ba BBC Yoruba sọrọ, Bode George ni ipinlẹ Eko lo jẹ gbese ju lẹyin ijọba apapọ lorilẹede Naijiria