Eid-el-Kabir: ''A ò rí èèyàn ra ẹran àgbò lọ́dún yìí bíi ọdún Iléyá tó lọ''
Ileya ti de, Ileya ti de o, Barka De Sallah ẹ ku ọdun. Pọpọsinsin ọdun Ileya bẹrẹ kaakiri orilẹede Naijiria ati lagbayee.
Ọpọ musulumi ni wọn ti ra ẹran agbo fun ayẹyẹ ọdun Ileya, ṣugbọn oniṣowo ẹran agbo ni Ojurin lagbagbe Alẹṣinlọyẹ niluu Ibadan, Ọgbẹni Fatai Ibrahim sọ fun BBC Yoruba pe awọn ẹran agbo t'oun ta ni ẹgbẹrun mẹẹdọgbọn nairia lọdun to lọ ti di ẹgbẹrun un mejilelogub bayii.

O ni idi abajọ naa ni wi pe awọn eeyan ko tu yaya jade ra ẹran bii ti ọdun Ileya to lọ.
- Ààrẹ Buhari ti lọ sí ìlú Daura fún ọdún Sallah
- Ìbànújẹ́ ni ọdún Orò ma ń jẹ́ fún àwọn obìnrin ní ìlú Ikorodu
- Ẹgbẹ́ òṣèlú AAC fi ọwọ́ òsì júwe ilé fún Ṣowore!
- Sowore ṣèpàdé pẹ̀lú Nnamdi Kanu láti dojú ìjọba Nàíjíríà bolẹ̀ - Àjọ DSS
- Lórí ìmọ̀ràn Sunday Igboho, Ẹlẹbubọn ní yóò dára kí Yorùbá padà sí àmúlò èròjà ìbílẹ̀ fún ààbò
- Fulani kò leè dúró, táa bá lo ohun ta jogún lọ́dọ̀ àwọn bàbá wa - Sunday Igboho