June 12: Lekan Alabi ní kí ọmọ Naijiria rántí àwọn akọni ìjọba àwa-arawa
Agbaakin Olubadan, Oloye Lekan Alabi ti ṣalaye bi ọrọ June 12 ṣe ri ni ọkan rẹ ati ọpọ ọmọ Naijiria lẹyin ti Aarẹ Muhammadu Buhari sọ June 12 di ayajọ ọjọ ijọba awa-arawa ni Naijiria lati yẹ MKO Abiola si.
Àwọn ìròyìn tí ẹ lè nífẹ̀ẹ́ sí:
- June 12 èso àwọn ohun málèègbàgbé nípa MKO••
- •'IBB dalẹ̀ Abiola lẹ́yìn tó búra pẹ̀lú Koran'
- Sé o ti rí ère MKO Abiola tuntun?
- MKO Abiola, iṣẹ́ aṣẹ́gità ló fi bẹ̀rẹ̀ okoòwò
- Ojú ará oko, ojú ará òkè ni wọ́n fi ń wo àwa ará Ekiti, mo fẹ́ tún Ekiti ṣe ni- Debo Ranti Ajayi
- Ẹ wo fídíò bí Ìyálóde Ìbàdàn se sùn tẹ̀yẹ-tẹ̀yẹ
- BBC Yorùba balẹ̀ bàgẹ̀ s'ílée MKO Abiola l'Eko