Ọbasanjọ: Buhari ń pète láti ka ẹ̀sùn èké si mi lọrùn

Buhari ati Ọbasanjọ nki ara wọn

Oríṣun àwòrán, @NGRPresident

Àkọlé àwòrán, Ọbasanjọ ti kọ lẹta tó fẹ̀sùn kan Buhari eleyi to di gbajugbaja kaakiri agbaye
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1

Ààrẹ àná orílèèdè Nàìjíríà, Olusegun Obasanjo, ti ke gbajare pe ìjọba Buhari n pète láti ka ẹsùn sí òun lọrùn.

Obasanjọ ní, ìjọba Buhari fẹ lo ayédèrú ìwé láti ṣe ìṣe aburú yìí.

Nínú atẹjade kàn láti ọwọ olùrànlọwọ rè lórí ọrọ ìròyìn, Kehinde Akinyemi, Obasanjọ ní, ọnà méjì ní wọn fẹ gba fí panpe mu òun.

Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:

''Àkọkọ ni pé, wọn fẹ ló àjọ to n gbogun ti iwa jegudu-jera, EFCC, láti bẹrẹ Ìwádìí padà lórí òhun tó ṣẹlẹ lasiko ìjọba mi''

''Ẹlekeji ni pé, wọn fẹ ló awọn ayédèrú ìwé kan láti ṣe àkóbá fún òun gẹgẹ bí wọn ti ṣe ṣe ní àsìkò ìjọba ológun Abacha.''

Kíni àwọn ọmọ Nàìjírìà ń sọ lórí ọ̀rọ̀ tí Obasanjọ lóri ìkànsíraẹni twitter:

Skip X post, 1
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 1

Skip X post, 2
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 2

Skip X post, 3
Allow X content?

This article contains content provided by X. We ask for your permission before anything is loaded, as they may be using cookies and other technologies. You may want to read X cookie policy and privacy policy before accepting. To view this content choose 'accept and continue'.

Warning: Third party content may contain adverts

End of X post, 3

Ọrọ yí láwọn kan ti ṣe àpèjúwe rè gẹgẹ bí èsì Obasanjo sí ìgbésẹ ìjọba Buhari, láti fi ọjọ ayajọ òṣèlú tiwá n tiwá da olóògbé Moshood Kasimawo Abiola lọla.