Yussuf Adekola: Olè ló sọ mi di aláìlẹ́sẹ̀ ṣùgbọ́n mo dúpẹ́ pé mo ṣì wà láyé
Iṣẹ wẹda ni mo kọ lati ọdọ Baba mi, ohun ni mo pada si lẹyin ti mo padanu ẹsẹ mi- Yussuf Adekola
BBC Yoruba wa Yussuf Adekola kan lẹyin iroyin nipa rẹ pe awọn gbewiri gba ọkada tuntun to ṣẹṣẹ ra.
Yussuf Adekola ṣalaye ohun ti oju rẹ ri lọjọ to gbe ero naa ti ko si mọ pe ole to fẹ gab ọkada tuntun ti oun ra ni.
O sọ bo ṣe rinrinajo aye rẹ to lo ọdun kan nile iwosan fun itọju ọpa ẹyin rẹ ti ole yinbọn si.
- O-hùn kan lójú oorun ló ní kí n gbàdúrà fún Tinubu ní ìhòhò- Olaiya Igwe
- N-LC ṣe ìwọ́de lórí ọmọ ọdún 22 tí ẹ̀rọ gé lọ́wọ́ ní iléèṣẹ́ tó n bá ṣiṣẹ́
- Ààrẹ láti ẹkùn gúsù Nàìjíríà ni mo fọwọ́sí fún ìdìbò 2023 – Obasanjo-
- Ààrẹ South Africa sọ̀rọ̀ sókè lẹ́yìn tí wọ́n fẹ̀sùn lílu $4m ní póńpó kàn án
- Èrò ọmọ Nàìjíríà ṣọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lórí àforíjìn Adamu, akẹ́kọ̀ọ́ fásiti tó sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí Aisha Buhari
Yussuf salaye bi aya rẹṣe kọọ silẹ lẹyin iṣẹlẹ naa, koda o ni pe ọpọ ọrẹ lo kọ oun silẹ ṣugbọn oun kó lati ṣe agbe.
O gba awọn to ni ipenija nimọran lati wa iṣẹ ọwọ kan ṣe tabi ọja tita lai maa ṣagbe.
Bakan naa lo fi imoore han si Oldoumare pe oun ṣi wa laye.
O ṣalaye ọna to fi bori ironu ati ibanujẹ ọkan ko to pada si idi iṣẹ jorinjorin.
- Iṣẹ́ fíìmù ló sọ mi di Babaláwo, Wòlíì Ọlọ́run ni mi - Adewale Alebiosu
- "Ọ̀pọ̀ ń gbàdúrà kí àwọn ní HIV báyìí"
- 'Ọkọ̀ mi máà ń tẹ̀lé mi lọ rehearsal Onílù ká tó gbéyàwó àmọ́ bí mo ṣe kó wọlé tán báyìí, ó di nǹkan míì...'
- Ṣé lóòtọ́- Bóo bá ń mu Garri jù tí wọ́n tàn ẹ́ pé ojú dídùn ni yóò gbẹ̀yìn rẹ; gbọ́ òótọ́ lẹ́nu onímọ̀
- Bàbá mi Alafin Oyo fẹ́ràn ipa tí mo kó nínú Sinimá Anikulapo, wọ́n sì fẹ́ wò ó àmọ́... - Adedoja Alaafin
- Ọ̀rọ̀ Japa dé Ekiti; 'Iléeṣẹ́ tó ní àwọn fẹ́ ran wá lọ́wọ́ lọ ìlú Òyìnbó ti -scam' wa, àìsàn déé!