Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Àkọlé fọ́nrán ohùn, Ko ṣe ma gbọ iroyin asiko
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Abisola Kola-Daisi, Ọmọ gomina ipinlẹ Oyo tẹlẹ, Abiola Ajimobi, ti jade laye.

Iku doro.

Owurọ Ọjọbọ ni iroyin ni iroyin sọ pe Abisola ku lorilẹ-ede United Kingdom lẹni ọdun mẹrinlelogoji

mmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmmm

Gomina Seyi Makinde ti yi ọrọ pada lori ofin Sharia l'Oyo

Ṣaaju lo ti loun yoo gbe igbimọ naa lọ si kootu.

Bayii nko?

Makinde sọ pe awọn to ba fẹ, le ko ẹjọ lọ siwaju igbimọ naa lati ba wọn dajọ, yala musulumi tabi ẹlẹsin miran

O ni eyi yoo din ẹjọ tawọn adajọ n gbọ ku

Amọṣa, Ọjọgbọn Isiaq Akintola, Oludasile ajọ MURIC to n ja fun ẹtọ Islam lawọn ko fẹ ki Kristẹni lo Sharia.

Akintola sọ pe Musulumi nikan lofin naa wa fun

Ki lo de ti MURIC sọ eyi lẹyin to ti n pe fun Sharia tipẹ

Ka a ni BBC.COM/YORUBA

,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,,

Orilẹede Niger ti bura fun Abdourahamane Tchiani gẹgẹ bi aarẹ ologun

Ọgagun Tchiani ni olori awọn ṣọja to gbajọba lọwọ aarẹ alagbada, Mohamed Bazoum lọdun 2023.

Ọdun marun ni yoo fi lo ipo, lẹyin to tu awọn ẹgbẹ oṣelu ka.