You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Àwọn nnkan tó yẹ kí o mọ̀ nípa àwọn olùdíje nínú ìdìbò ààrẹ Ghana
Ìye àkókó tí a fi kà á: Ìṣẹ́jú 1
Ọjọ Abamẹta, ọjọ kẹjọ, oṣu Kejila, ọdun 2024, ni eto idibo aarẹ yoo waye ni orilẹ-ede Ghana.
Lara awọn to n dije lati gba ipo lọwọ Aarẹ Nana Akufo-Addo, ni igbakeji rẹ, Mahamudu Bawumia, ẹni ọdun mọkanlelọgta.
Bakan naa ni aarẹ orilẹ-ede naa nigba kan, John Dramani Mahama, naa tun n dije lati pada di aarẹ.