Ọdọbinrin Iyeyemi Adediran sọ iriri rẹ ni idi iṣẹ awakọ epo tirela ati bi o ṣe bẹrẹ.
Arabinrin Iyeyẹmi Adediran ni igbagbọ ohun ni pe ko si ohun ti ọkunrin le ṣe ti obinrin le ṣe.
Iyeyẹmi sọ eyi lasiko to n ba BBC Yoruba sọrọ lori iriri rẹ ni idi iṣẹ awakọ epo tirela ati bi o ṣe bẹrẹ.
O ni ọdun mẹrin niyii ti oun ti bẹrẹ iṣẹ awakọ ti oun si n gbiyanju lojojumọ lati ṣiṣẹ karakara.
- Tí wọn kò bá tètè dá ASUU lóhùn, a óò gùnlé ìyansẹ́lódì ọlọ́jọ́ mẹ́ta- NLC
- Ọwọ́ ti tẹ obìnrin kan lórí ẹ̀sùn ọmọ tuntun tó dàwátì ní Ibadan- Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
- Ìgbẹ́jọ́ olùṣirò àgbà Naijiria tẹ́lẹ̀, Ahmed Idris ń tẹ̀síwájú lónìí lórí ẹ̀sùn lílu ₦80b ní pónpó
- Wọ́n ti yọ Portable bíi jìgá kúrò nínú àwọn tí yóò gba àmì ẹ̀yẹ ‘Headies’ nítorí wòtòwótò
Bakan naa lo ni oun ko yan iṣẹ naa laayo nitori pe ko si iṣẹ amọ nitori oun fẹran ọkọ wiwa ti oun si ti ri obinrin to ti wa ọkọ naa.