BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Fídíò
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
03:19
Fídíò,
Ṣé lóòótọ́ ní òògùn owó ṣíṣe wà? Babaláwo ṣàlàyé
, Duration3,19
01:34
Fídíò,
Ìbẹ̀rùbojo àti ìpayà ni àdó olóró Trump tó ṣèṣì balẹ̀ sínú Offa kó sí wa lọ́kàn - Aráàlú
, Duration1,34
02:34
Fídíò,
Kì í ṣe owó Baba Okoya nìkan ni mo ń ná - Raheem Okoya
, Duration2,34
02:46
Fídíò,
Ọmọ mi méjì, ọmọ ìyáálé mi kan ni Amọtẹkun pa ni Akinlalu l'Osun, ìdájọ́ òdodo ni mo fẹ́ - Arábìnrin Oyebamiji
, Duration2,46
04:07
Fídíò,
Àlàyé lórí ìdí tí àjọ NSCDC Ondo ṣe lo ìwà ipá pẹlu obìnrin tó pọnmọ sẹ́yìn àti ọkọ rẹ lórí ọ̀rọ̀ títa afẹ́fẹ́ gáàsì
, Duration4,07
03:00
Fídíò,
Ọ̀dọ́mọdé Kábíyèsí tó ń kẹ́kọ̀ọ́ ní fásítì bó ṣe ń ṣàkóso ilú sọ ìrírí rẹ̀ lórí oyè
, Duration3,00
04:12
Fídíò,
Nítorí tíátà làwọn òbí mi fi fàáké kọ́rí pé àwọn kò ní rán mi lọ sílé ẹ̀kọ́ – Ajanbadan
, Duration4,12
01:46
Fídíò,
Kí ló ń fàá tí àwọn obìnrin kan fi máà tètè dáwọ ṣíṣe nǹkan oṣù dúró?
, Duration1,46
04:01
Fídíò,
'Ile Ife ni àwa Ijebu ti wá ṣùgbọ́n ìtàn náà pín sí méjì'; wo ìtàn bí Ijebu ṣe ṣẹ̀ wá
, Duration4,01
03:16
Fídíò,
Hauwa Lawal, gbajúmọ̀ lórí ayélujára dá sí 'Sóo láyà?'
, Duration3,16
03:48
Fídíò,
Wo òkúta tó sọ ìlú Ilorin lórúkọ tó ń jẹ́
, Duration3,48
Ìròyìn tó ṣe kókó
Iran da padà, bẹ̀rẹ̀ ìkọlù sáwọn iléeṣẹ́ ológun Amẹ́ríkà tó wà ní Middle East
wákàtí kan sẹ́yìn
Ẹ wọ́gilé ìsìn ìṣọ́ òru nítorí ètò àbò tó mẹ́hẹ – Ọlọ́pàá Ondo kìlọ̀ fáráàlú
wákàtí 4 sẹ́yìn
Ilupeju Ekiti: Ìlú tí ọmọ bíbí rẹ̀ kò gbọdọ̀ ṣe oògùn owó
wákàtí 8 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Ọ̀fọ̀ ńlá tún ṣẹ̀ lágbo tíátà, àgbà òṣèré, Okemesi jáde láyé
25 Èrèlè 2026
Akẹ́kọ̀ọ́ Ilé ẹ̀kọ́ fásítì LAUTECH mẹ́fà tó ń lọ ṣèdánwò àṣekágbá pàdánù ẹ̀mi wọn nínú ìjàmbá ọkọ̀
25 Èrèlè 2026
Ṣé lóòótọ́ ní ìjọba Naijiria san ₦2bn fún Boko Haram fún ìtúsílẹ̀ akẹ́kọ̀ọ́ 230 tí wọ́n jí gbé? Ohun tí a mọ̀ rèé
24 Èrèlè 2026
Iná ṣẹ́yọ ní pápákọ̀ òkúrufú ìlú Eko, òṣìṣẹ́ FAAN dèrò ilé ìwòsàn
24 Èrèlè 2026
Àwọn agbébọn tún ṣekú pa èèyàn méjì ní Kwara, èèyàn kan f'arapa
24 Èrèlè 2026
Kí ló ṣẹlẹ̀ láàárín Wale Akorede Okunnu àti Olasco Films tí wọ́n fi ń tahùn síra lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ọdún?
24 Èrèlè 2026
El-Rufai bèèrè ₦1bn lọ́wọ́ ICPC nílé ẹjọ́, DSS ní àfi kó fojú ba ilé ẹjọ́
24 Èrèlè 2026
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko kéde àfikún owó ọkọ̀ BRT, Wo iye tó jẹ́, ìgbà tí yóò bẹ̀rẹ̀ àti ìdí abájọ
24 Èrèlè 2026
Ilẹ̀kùn Al-Jannah máa ń ṣí sílẹ̀, ilẹ̀kùn ọ̀run àpáàdì máa ń wà ní títì pa lásìkò ààwẹ̀ Ramadan - Imaamu Agba
23 Èrèlè 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Iran da padà, bẹ̀rẹ̀ ìkọlù sáwọn iléeṣẹ́ ológun Amẹ́ríkà tó wà ní Middle East
2
Ẹ wọ́gilé ìsìn ìṣọ́ òru nítorí ètò àbò tó mẹ́hẹ – Ọlọ́pàá Ondo kìlọ̀ fáráàlú
3
Ọfà ni wọ́n ta mọ́ mí tó sọ mi di arọ, àwọn tó wà nídìí ọ̀rọ̀ mi kò jáwọ́ lẹ́yìn tí mo gbádùn tán - Ọ̀rọ̀ tí Okemesi sọ kó tó kú
4
Wo ohun tó mú Busola Oke 'Eleyele' sunkún tó ń fa awuyewuye lórí ayélujára
5
Wá ojútùú sí ètò ààbò tó mẹ́hẹ kó o sì dáàbò bo ọmọ Naijiria, Alaafin àti Ooni gba Tunji Disu n'ímọ̀ràn
6
Tinubu wọ aṣọ Ọ̀gá ọlọ́pàá Naijiria fún Disu lẹ́yìn tí Egbetokun gbé àkóso iléeṣẹ́ ọlọ́pàá lé e lọ́wọ́
7
Ohun tí ṣíṣe àtúntò iléeṣẹ́ ọlọ̀pàá túmọ̀ sí fún Nàìjíríà
8
Àjọ INEC kéde ọjọ́ tuntun fún ìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Osun, ètò ìdìbò Ààrẹ 2027
9
Ẹ̀dà ìwé ìdájọ́ tó rán Ọba Ipetumodu lẹ́wọ̀n l'Amerika tẹ àwọn ìdílé ọba lọ́wọ́.
10
Pásítọ̀ ń sanwó wáàsí mi lórí rédíò, ó fi ń ṣe ìwàásù ní ṣọ́ọ̀ṣì - Akeugbagold
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 25 Èbibi 2020
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology