BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
00:52
Fídíò,
Àwọn aṣọ aláràmbarà tí wọ́n lò níbi ayẹyẹ AMVCA
, Duration0,52
03:29
Fídíò,
"Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé"
, Duration3,29
01:30
Fídíò,
"Iṣẹ́ tóo yàn láàyò lè ṣàkóbá fún ìlera ọpọlọ rẹ lọ́jọ́ alẹ́"
, Duration1,30
01:36
Fídíò,
Ìwádìí BBC tú àṣírí àwọn tó ń fi ajá tó ṣèse lú jìbìtì gbowó lórí ayélujára
, Duration1,36
03:25
Fídíò,
Wọ́n pe pásítọ̀ kó wá ṣe ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ̀ṣì ni káwọn agbébọ̀n tó yìnbọn paá – Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí ìkọlú àwọn agbébọn sí ṣọ́ọ̀ṣì kan l'Ekiti
, Duration3,25
01:13
Fídíò,
Ìdí rèé tí ọ̀dà tí o fi ń kun irun rẹ sí àwọ̀ mìràn ṣe lè fa jẹjẹrẹ ọyàn fún ọ
, Duration1,13
03:19
Fídíò,
"Igede Ekiti ni ilé Osun, omi rẹ̀ sàn dé Osogbo ni, ohun tó mú u yíra padà kò di odò ńlá rèé"
, Duration3,19
01:59
Fídíò,
Ǹ jẹ́ ẹ mọ nípa Ọdún Ẹlẹ́gba Èjìwà l‘Eko níbi tí takọ-tabo kìí wọ aṣọ tàbí bàtà?
, Duration1,59
01:41
Fídíò,
Ìjà ìlú wa là ń gbè, a gbà, tí ẹ bá ní à ń ṣe ìwà ipá sáwọn àjèjì - Àwọn ọmọ South Africa ṣe ìwọ́de
, Duration1,41
04:52
Fídíò,
"Ìdí rèé tí mo ṣe fi àkàrà òyìnbó mọ ṣọ́ọ̀ṣì kàtídírà ńlá, èyí tó jẹ́ ìyanu fún ọ̀pọ̀ èèyàn"
, Duration4,52
02:10
Fídíò,
Ohun tí a mọ̀ rèé lórí ohun tó fa ìkọlù ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ nílẹ̀ Mali èyí tó mú ọ̀pọ̀ ẹ̀mí lọ
, Duration2,10
02:01
Fídíò,
Lisabi 2026: Wo bí àwọn ọmọ Abeokuta ṣe dábírà níbi ayẹyẹ ìrántí akọni wọn
, Duration2,01
01:21
Fídíò,
Tí àtọ̀ ọkùnrin kò bá lágbára tó, àwọn ìṣòro tó lè dá sílẹ̀ fún obìnrin rèé
, Duration1,21
Ìròyìn tó ṣe kókó
Gbajúmọ̀ òṣèré jáde láyé lẹ́ni ogójì ọdún
12 Èbibi 2026
Ìdí rèé tí ẹgbẹ́ òṣèlú NDC fi gbé ipò Ààrẹ sí ìhà gúúsù lọ́dún 2027, Peter Obi ni olùdíje ààrẹ, èmi ni igbákejì rẹ̀ - Kwankwaso
12 Èbibi 2026
Lẹ́yìn tí ajínigbé gba N50m owó ìtúsílẹ̀, wọn pa àgbà olóṣèlú lẹ́gbẹ́ ADC, fi òkú rẹ̀ ránṣẹ́
12 Èbibi 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wọ́n bá òkú ọmọ ọdún mọ́kànlélógún nínú yàrá l'Osun, ariwo sọ
8 Èbibi 2026
Kí ló mú Davido ṣẹ́wélé orin kíkọ fún oṣù méjì báyìí? Àlàyé rèé
8 Èbibi 2026
Egúngun tó lé obìnrin kan láì dẹ̀yìn jìyà àjẹpọ́nnulá; Obìnrin náà ṣíṣọ lójú rẹ̀ níta gbangba ló bá di ọkọ rẹ̀
8 Èbibi 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá VCRU tuntun, ìdí fún ìdásílẹ̀ rẹ̀ àti iṣẹ́ àwọn ọlọ́pàá náà
8 Èbibi 2026
A ò tíì wẹ̀ láti ọjọ́ mẹ́ta, kò sí ìná, kò sí omi – Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ fásitì Ibadan figbe ta
6 Èbibi 2026
Ọkùnrin méje tó ṣe pàṣí-pààrọ̀ ìyàwó bọ́ sọ́wọ́ àwọn ọlọ́pàá Hisbah
7 Èbibi 2026
Ohun tó dùn mi jùlọ láyé lọ̀rọ̀ tí ìyàwó mi sọ pé méjì nínú ọmọ márùn ún tí mo ṣe súná wọn kìí ṣe tèmi - Òṣèré tíátà, Tioruju
7 Èbibi 2026
Kí ló fa gbas-gbos láàárín Akpabio àti Oshiomhole nílé ìgbìmọ̀ aṣòfin, àlàyé rèé
7 Èbibi 2026
Bàbá Mohbad fẹ́ jogún ọmọ rẹ̀; mi ò lè fun ní ohun tó ń fẹ́ – Wumi Aloba
7 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Gbajúmọ̀ òṣèré jáde láyé lẹ́ni ogójì ọdún
2
Àlàyé rèé lórí ìdí tí ọkọ̀ òfurufú tó ń bọ̀ láti Amẹ́ríkà, tó yẹ kó balẹ̀ l‘Eko padà láì já èrò inú rẹ̀, lẹ́yín tó dúró fún wákàtí mẹ́jọ lójú òfurufú
3
Lẹ́yìn tí ajínigbé gba N50m owó ìtúsílẹ̀, wọn pa àgbà olóṣèlú lẹ́gbẹ́ ADC, fi òkú rẹ̀ ránṣẹ́
4
Láì ṣe IVF, obìnrin kan bímọ márùn-ún lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo lẹ́yìn tó fi ọdún méjìlá yàgàn
5
Ìdí rèé tí ẹgbẹ́ òṣèlú NDC fi gbé ipò Ààrẹ sí ìhà gúúsù lọ́dún 2027, Peter Obi ni olùdíje ààrẹ, èmi ni igbákejì rẹ̀ - Kwankwaso
6
Àwọn onímọ̀ ṣàwárí obìnrin tó bí ìbejì táwọn ọmọ náà sì ní bàbá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀
7
Àlàyé rèé lórí ohun táwọn iléeṣẹ́ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ ṣe tí ìjọba àpapọ̀ ṣe fọnmú mọ́ wọn lọ́wọ́
8
Egúngun tó lé obìnrin kan láì dẹ̀yìn jìyà àjẹpọ́nnulá; Obìnrin náà ṣíṣọ lójú rẹ̀ níta gbangba ló bá di ọkọ rẹ̀
9
Ṣé lóòótọ́ ni àdó olóró tí ológun Chad jù fún Boko Haram pa ọ̀pọ̀ apẹja ọmọ Naijiria?
10
Kí ló mú kí ọkọ̀ kan ré bọ́ láti orí afárá sí ìsàlẹ̀ èyí tó pa èèyàn mọ́kànlá l‘Ogun?
More:
News
•
Sport
•
Weather
•
Worklife
•
Travel
•
Future
•
Culture
•
World
•
Business
•
Technology
•
Science_and_environment
•
Entertainment_and_arts