"Wasiu Ayinde fi bàtà tẹ̀ mí lórí àti imú mọ́lẹ̀, ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ gbá mi létí"
Ni owurọ ọjọ Abamẹta ni ariwo gba ilẹ kan pe, ilumọọka akọrin Fuji ati Mayegun ilẹ Yoruba, Wasiu Ayinde Mashall, ti ọpọ eeyan mọ si Kwam 1, gba gbajumọ agbohunsafẹfẹ kan leti loju agbo.
Orukọ ilumọọka agbohunsafẹfẹ naa ni wọn pe ni Wole Sorunke, ti ọpọ eeyan mọ si MC Murphy, ẹni tii se oludari eto gbogbo nileesẹ radio Fresh FM to wa nilu Abeokuta.
Gẹgẹ bi iroyin naa se wi, nibi ayẹyẹ ọjọ ibi ọgọta ọdun Olu tilu Itori, Ọba Abdulfatai Akorede Akamọ ni isẹlẹ naa ti waye, lasiko ti wọn pe Kwam 1, ko wa kọrin nibẹ.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Sunday Igboho kàn ń gbé ‘Camera’ lẹ́yìn kiri, kí wọ̀n lè rò pé ó ń jà fún Yorùbá - Gani Adams
- Donald Trump dèrò ilé ìwòsàn torí àrùn Coronavirus tó mu
- Ìlànà ‘Referendum’ nìkan la fi le gba orílẹ̀èdè Oduduwa, kìí ṣe ìwọ́de
- Aṣọ́bodè ṣèèsì pa ‘Panel Beater, aya mẹ́rin àti ọmọ 18 ń bẹ̀bẹ̀ fún ìrànwọ́
- ₦750m ni Akeredolu ń gbà lóṣù fún ‘Security Vote’ àti ₦150m owó oṣù - Agboola Ajayi fèsì
- INEC kéde agbègbè ẹsẹ̀ odò 270 ti èrú ìbò ti le wáyé ní ìpínlẹ̀ Ondo
- Ẹgbẹ́ tó ń fẹ́ Oduduwa Republic kọ̀wé ẹ̀hónú sí UN, EU, AU àti ìjọba Gẹ̀ẹ́sì
- Àjọ EFCC ti mú ọ̀dọ́kùnrin mẹ́wàá lórí ẹ̀sùn jìbìtì lílù lórí ayélujára ní Oyo
- Irọ́ ni o! Ìyàwó Ọ̀ọ̀ni Ogunwusi kò bímọ tuntun