Eld Kabir in Nigeria: Mùṣùlùmí àti Kristiẹni sọ̀rọ̀ nípa àdun oúnjẹ́ àti ẹran ọdún Ileya
Loni ọjọ Ẹti ni ayajọ ọdun Ileya fun tọdun yii taa mọ si Eid Kabril.
Gẹgẹ bẹẹ se mọ pe awọn ọmọde ati agba maa n foju sọna fun ọdun alarinrin yii nitori awọn adun kan to wa ninu rẹ.
Idi ree ti BBC Yoruba fi gbe igbimọ kan kalẹ ninu eyi ta ti ri awọn musulumi ati Kristiẹni, ti wọn ti jiroro nipa awọn adun to wa ninu ọdun Ileya.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Kí ìjọ mi ní Sagamu le gbòòrò ni mo fi ń ṣiṣẹ́ ajínigbé pawó - Pásítọ̀
- Àwa àti fijilanté pẹ̀lú ọdẹ́ ìbílẹ̀ ló dojú kọ adigunjalè ní First Bank Okeho - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
- Ìtàn ọba Yorùbá tí wọn yẹgi fún torí ó jí ọmọ gbé ṣe ètùtù
- Ẹ káàbọ̀ sọ́jọ́ Arafat, tí Ọlọ́run yóò fi ààwẹ̀ Mùsùlùmí pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́
- "Ọmọ mi kò tíì mọ̀ pé òun ti di ìlúmọ̀ọ́ká, ó ń wádìí bó ṣe ń rí ara rẹ̀ lórí ayélujára"
- Boko Haram da ìbọn bo ọkọ̀ gómìnà Borno, ẹ̀ṣọ́ àláàbò rẹ̀ farapa
Lara ohun ti wọn mẹnuba ni ẹran dindin, ounjẹ ọdun, owo ọdun ati asọ ọdun.
Bakan naa ni igbimọ yii tun mẹnuba bi ọdun Ileya se maa n larinrin lasiko igba ti wọn wa ni ewe atawọn ọna ti wsn n gba gbadun rẹ.