Nigeria Elections 2019: Èrò àwọn ọmọ Nàíjíríà se ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lóri ètó àlùfáà tàbí ìmámù lásìkò ìbò
Ọpọlọpọ awọn ọmọ Naijiria sọ wi pe, adari ile ijọsin tabi imaamu wọn ko le e sọ fun wọn, ẹni ti wọn yoo dibo fun nitori pe ẹtọ awọn ni lati dibo yan ẹni to wu awọn.
Amọ, awọn miran sọ wi pe, alufaa awọn mọ ẹni to daraju laarin awọn oludije, nitorina awọn le e tẹle imọran rẹ lasiko idibo.
Àwọn iròyin tì ẹ leè ní ìfẹ̀ síí:
- Ìbòòsí! Wọ́n fẹ́ ṣe màgòmágó ìbò tó ń bọ̀ - Danjuma figbe bọnu
- Ẹgbẹ́ òsìsẹ́ NLC ti kọ #27,000 owó osù òsìsẹ́
- Gomina Fayemi jáwé lọ gbé ilé rẹ fún adarí fasiti Ekiti
- Lẹ́yìn òkò ọ̀rọ̀, Buhari àti Ọbasanjọ fẹ̀rín pàdé ara wọn l‘Abuja
- Ẹṣin to n jó léti òkun di orísun ọrọ̀ l'Eko
- Àrà méèrírí , ẹ wo ọkùnrin tí eegun rẹ̀ rọ̀ bíi rọ́bà, tó ń ká bíi ẹja
- Exclusive: Atiku dára ju Buhari ní ìlọ́po méjì - Obasanjo #BBCNigeria2019