
Awọn afunrasi ikọ agbẹsunmọmi Boko Haram se ikọlu si ile-ẹkọ Girama fun awọn obinrin ni ilu Dapchi, nipinlẹ Yobe, ni ila-ariwa orilẹede Naijiria.
Awọn akẹẹkọbinrin Dapchi mẹrindinlaadofa ati ọmọdekunrin kan ti ṣepade pọ pẹlu Aarẹ Muhammadu Buhari ni Abuja to jẹ olu-ilu Naijiria.
Ewọ akojọpọ iroyin bii wọn ṣe ji awọn ọmọ Dapchi naa gbe titi di ọjọ ti mẹrindinlaadofa (106) fi gba itusilẹ.