Olori Tobi Phillips Ogunwusi: Ajọṣepọ̀ èmi àti àwọn Olori Ooni Ile Ife tó kù dán mọ́ran gidi
Bí mo ṣe pàdé Ooni Ile Ife rèé, ki n to di Olori lọọdẹ ẹni bi ọkan mi- Olori Tobi Phillips Ogunwusi.
Olori Tobi Phillips Ogunwusi, ọkan lara awọn olori ẹlẹ Ooni ti Ile Ife gbalejo BBC Yoruba.
Olori sọrọ ni kikun lori itan igbesi aye rẹ ko to di arinrinoge, aranṣọ, amunidara ati ayaworan.
Bakan naa lo mẹnuba bo ṣe pade Ojaja Keji ti ọrọ ifẹ wọn si fi wọ ti oun naa fi di olori.
O tun sọ awọn idojukọ re ati bo ṣe bori pẹlu ero rẹ lori ile olorogun.
Wo bi oriki Ooni Ile Ife , oba Adeyeye Ogunwusi se dun lenu olori Tobi Phillips Ogunwusi yii.
- Àrà méèrírí! Ọkùnrin tí kò ríran kan rèé tó ń lọ ẹ̀rọ ata
- ‘Ò dà bí àlá bí mọ ṣe da ìlúmọ̀ọ́ka nítorí bí a ṣe ń gbé òkú jó ní Ghana’
- Alífábẹ́ẹ́tì Ohùn Oduduwa di ìtẹ́wọ́gbà ni Ajaṣẹ
- Àsìkò wo ló yẹ kí obìnrin bẹ̀rẹ̀ ìbálòpọ̀ padà lẹ́yìn ìbìmọ láìséwu?
- Ojú wa rí tó lásìkò tì a wà ní àhámọ́ ajínigbé, koríko la jẹ fún ọjọ́ 52