You’re viewing a text-only version of this website that uses less data. View the main version of the website including all images and videos.
Coronavirus Update in Namibia vs elephant: Ṣé òótọ́ ni pé ìgbẹ́ erin le è wo arùn Covid-19 sàn?
Ibeere nla to gab ọkan awọn eeyan orilẹ̀-ede Namibia ni ilel Afrika ni yii
Minisita eto ilera orilẹ-ede Namibia, Kalumbi Shangula ti kilọ fun awọn ọmọ orile¬̣-ede naa pe ki wọn sọra fun lilo igbẹ erin fun iwosan arun Covid-19.
Ṣaaju ni awọn oniwosan ibilẹ kan ti kọkọ sọ pe igbẹ erin le e koju aisan ọfinkin, ori fifọ ati lati dawọ ẹjẹ to n ṣan lati imu duro ti wọn ba le e gbe igbẹ naa gbona ki wọn si fi imu.
Ṣugbọn ko tii si ẹni to tii fi idi igbesẹ naa mulẹ ninu imọ sayẹnsi pe o lagbara lati wo ikọkan ninu awọn aisan ọhun.
Shangula ni omi inu n kan oun pe awọn kọlọrọsi kan le e gba owo lọwọ awọn eeyan fun awọn oogun tabi iwosan ti ko ṣiṣẹ.
- Adamu Adamu, Minista ètò ẹ̀kọ́ ti fi òfin àátẹ̀lẹ́ síta kí àwọn ilé ìwé lè wọlé
- Ikú Williams Aanuoluwa lágbo òṣèré hú ọ̀pọ̀ ọ̀rọ̀ síta
- Boko Haram ṣọṣẹ́ ní Borno, wọ́n sé àwọn èèyàn mọ́lé ní Kukawa
- Wo ìdí tí Osun fi kede ìsinmi fún ọdún ìṣẹ̀ṣe, tàwọn ìpínlẹ̀ yókù kò dáhùn,
- Ilé ẹjọ́ yá lórí òfin CAMA tó fẹ́ gba àkóso ilé ìjọsìn, tẹ ẹ̀tọ́ aráàlú mọ́lẹ̀ - SERAP
Lọwọ yii, eeyan 4,464 lo ti lugbadi arun Coronavirus ni Namibia, ti awọn mẹtadinlọgbọn si ti jẹ Ọlọrun nipe.
Ọ̀rọ̀ coronavirus to je ajakale arun yii ni awọn oirlẹ-ede kan ti n bọ lọ́wọ́ re ti awọn mii si n ba jagun bayii
Titi di asiko yii ni ajọ eleto ilera agbaye WHO ni ko tii si oogu ati abẹrẹ ajẹsara kan ni pato ti iṣẹ ti pari lori é to le wo ajakale arun Covid 19 san bayii
- Mo fẹ́ kí Ọlọ́run fún wa ní ọmọ olójú búlúù si lẹ́yìn yìgì - Ọkọ olójú búlúù
- Afurasí lórí ikú Tolulope Arotile ti dé ilé ẹjọ́, èyí ni ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn án
- Ẹ̀yin gómìnà, Ifá nìkan ló le tọ yín sọ́nà láì kùnà lórí Amotekun - Babaláwo
- Kí ló ń ṣẹlẹ̀ lọ́wọ́ sí Mamman Daura àti ìlera rẹ̀?
- Ọdún Hijri mùsùlùmí tuntun wọlé dé, ẹ wo kókó pàtàkì nípa rẹ̀